< Lukha 3 >
1 Lino umwakha gwa kumi na tano ugwa nkilunga kesari Tiberia, imisikhi Pontio Pilati ale gavana va va yuta, Uherode alimbaha va nkoa gwa Galilaya, nu Filipo ulukololwe ale imbaha va unkoa gwa Iturea na kwu Trakoniti, na Lisania ale mmbaha va nkoa gwa Abilene,
Ní ọdún kẹ́ẹ̀dógún ìjọba Tiberiu Kesari, nígbà tí Pọntiu Pilatu jẹ́ baálẹ̀ Judea, tí Herodu sì jẹ́ tetrarki Galili, Filipi arákùnrin rẹ̀ sì jẹ́ tetrarki Iturea àti ti Trakoniti, Lisania sì jẹ́ tetrarki Abilene,
2 nu nsikhi gwa kuhani umbaha u Anasi nu Kayafa, ilimenyu lya Nguluve likha mwichela u Yohana umwana va Sakhaliya, khulunalawe.
tí Annasi òun Kaiafa ń ṣe olórí àwọn àlùfáà, nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Ọlọ́run tọ Johanu ọmọ Sekariah wá ní ijù.
3 Agendile unkoa gwoni ukhuchungula Inyanja Yolidani, alikhulumbilila ulwocho lwa khupela ulusyiekhilo lwa mbivi
Ó sì wá sí gbogbo ilẹ̀ aginjù Jordani, ó ń wàásù ìtẹ̀bọmi ìrònúpìwàdà fún ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀,
4 Nduvu yisimbiwe amemenyu mwa myamalago u Isaya, “Elimenyu lya munu uviilela mundunyikha, “Mnochage Injila ya Nkuludeva, Mnochage umwigendela umwene yigolokhage.
bí a ti kọ ọ́ nínú ìwé ọ̀rọ̀ wòlíì Isaiah pé, “Ohùn ẹni tí ń kígbe ní ijù, ‘Ẹ tún ọ̀nà Olúwa ṣe, ẹ mú ipa ọ̀nà rẹ̀ tọ́.
5 Amaguli goni gisyeliwa, ifyamba nu twamba finovhiwa, imisewe ugubendile gigolokha, ninjila imbivi chigolokha.
Gbogbo ọ̀gbun ni a yóò kún, gbogbo òkè ńlá àti òkè kékeré ni a ó tẹ́ pẹẹrẹ. Wíwọ́ ni a ó ṣe ní títọ́, àti ọ̀nà gbọ́ngungbọ̀ngun ni a o sọ di dídán.
6 Avanu voni yavikhovovona uvupokhi vwa Nguluve.”
Gbogbo ènìyàn ni yóò sì rí ìgbàlà Ọlọ́run.’”
7 Pwo, Yohana akhavavula anyaulundamano uhivaha lwa vanu uvuvagendile lekhe vochiwe nu mwene, “Umwe mwi khipapo kya njokha muvele ni sumu veni uviavavolile ukhunjila uvuhigi uvuyakhave vukhwicha?
Nígbà náà ni ó wí fún ọ̀pọ̀ àwọn ènìyàn tí ó wá láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Ẹ̀yin ìran paramọ́lẹ̀, ta ni ó kìlọ̀ fún un yín láti sá kúrò nínú ìbínú tí ń bọ̀?
8 Holaga Isekhe khikongana nu lukhuto pwo mlekhe ukhuchova mgati nayomwe, “Tulinu Ibrakimu vi dada veto; ulwakuva ni khuvavula ukhuta Unguluve, iwesya ukhuhalila u Ibrahimu avana ndagave mawe aga.
Nítorí náà kí ẹ̀yin kí ó so èso tí ó yẹ fún ìrònúpìwàdà, kí ẹ má sì ṣe sí í wí nínú ara yín pé, ‘Àwa ní Abrahamu ní baba.’ Kí èmi kí ó wí fún un yín, Ọlọ́run lè gbé ọmọ dìde fún Abrahamu nínú òkúta wọ̀nyí.
9 Lino isokha yivikhivwe pa malela ga mmbikhi pwu lino umbikhi gwu gwoni ugusagwihola isekhe inonu, gugidiwa nu khutaga mmwoto.
Àti nísinsin yìí pẹ̀lú, a fi àáké lé gbòǹgbò igi náà, gbogbo igi tí kò bá so èso rere, a óò ge lulẹ̀, a sì wọ jù sínú iná.”
10 Pwu avanu palulundamano vakha mbucha vakhata,” Pwu yinogwa tugahendakhikhi?”
Àwọn ènìyàn sì ń bi í pé, “Kí ni kí àwa kí ó ṣe?”
11 Akhavanda akhata, “Umunu unyalini khanzu ivili ahumye yimo ampe uyunge uvialivuvule ficho ingave alini khyalya agahe evwo.”
Ó dáhùn ó sì wí fún wọn pé, “Ẹni tí ó bá ní ẹ̀wù méjì, kí ó fi ọ̀kan fún ẹni tí kò ní; ẹni tí ó bá sì ní oúnjẹ, kí ó ṣe bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.”
12 Pwu avange avasonga songa vakhicho khwukwochiwa, pwu vakhembula, “Immanyiai, Tunongivwa tugale ndakhekhi?
Àwọn agbowó òde sì tọ̀ ọ́ wá láti ṣe ìtẹ̀bọmi lọ́dọ̀ rẹ̀, wọ́n sì bi í pé, “Olùkọ́, kí ni àwa ó ha ṣe?”
13 Akhavavula, “Mlekhe ukhutola indalana nyingi ficho icho sayinogiwa ukhutola.”
Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe fi agbára gbà jù bí a ti rán yín lọ mọ́.”
14 Avange avasikhali navope vakha mbucha, “Na yufwe? Tulondiwa tugahe ndakhe khi?” Akhavavula mlekhe ukhutola khumunu uvi avechaga khumakha khange mlekhe ukisile khumunu uvi avechaga kuvudesi, mkelage ni misahala gyimyo.”
Àwọn ọmọ-ogun sì béèrè lọ́dọ̀ rẹ̀ pé, “Àti àwa, kí ni àwa ó ṣe?” Ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ má ṣe hùwà ipá sí ẹnikẹ́ni, kí ẹ má sì ṣe ka ẹ̀sùn èké sí ẹnikẹ́ni; kí òwò ọ̀yà yín tó yín.”
15 Pwu lino ulwakhuva avanu vukhale nuvunogwqe vwa khugula u Kristi uviye khave ikwicha, khila akhava isaga munumbula ya mwene ukhuta u Yohana pange iva vi Kristi.
Bí àwọn ènìyàn sì ti ń retí, tí gbogbo wọn sì ń rò nínú ara wọn nítorí Johanu, bí òun ni Kristi tàbí òun kọ́;
16 UYohana akhanda akhavavula voni, “Une nikhuvocha umwe na magasi, pwu kwali umpamato ayikwicha uvi alinamakha khulina, khage saninogile ukhuvupola imilegeha gya fikato fya mwene ikwu vocha umwe nu mepo umbalache nu mwoto.
Johanu dáhùn ó sì wí fún gbogbo wọn pé, “Lóòótọ́ ni èmi ń fi omi bamitiisi yín, ṣùgbọ́n ẹni tí ó lágbára jù mí lọ ń bọ̀, okùn bàtà ẹsẹ̀ ẹni tí èmi kò tó tú, Òun ni yóò fi Ẹ̀mí Mímọ́ àti iná bamitiisi yín.
17 Uluhelo lwa mwene lulimmavokho ga mwene ukhonocho vunonu uwanda vwa mwene nu ukhupetela mgano nu khulundamania nkibana kya mwene. Pwu, ayinyunyania amapunji nu mwoto ugwu sagichima.
Ẹni tí àtẹ rẹ̀ ń bẹ ní ọwọ́ rẹ̀, láti gbá ilẹ̀ ìpakà rẹ̀ mọ́ tó tó, kí ó sì kó alikama rẹ̀ sínú àká; ṣùgbọ́n ìyàngbò ni yóò fi iná àjóòkú sun.”
18 Kumavungu agange mingi khange, alikhulumbilila inongwa inonu kwa Yesu.
Johanu lo oríṣìíríṣìí ọ̀rọ̀ púpọ̀ láti gba àwọn ènìyàn níyànjú àti láti wàásù ìyìnrere fún wọn.
19 UYohana akhadukha khange khwa Herode umbaha va nkoa pa khutola u Herodia, ichinge nyingi icho Herode alikhuvomba.
Ṣùgbọ́n nígbà ti Johanu bú Herodu tetrarki, tí ó bá wí nítorí Herodia aya Filipi arákùnrin rẹ̀, àti nítorí ohun búburú gbogbo tí Herodu tí ṣe,
20 Pwu khuvulongolo u Herode akhavomba uvuvivi uvunge uvuvala ficho akhandindila uYohani mligelesya.
Ó fi èyí parí gbogbo rẹ̀ nígbà tí ó fi Johanu sínú túbú.
21 Pwu yikhahumila ukhuta, unsikhu avanu voni upwu valikhwochiwa nu Yohana, na yu Yisu alikhwochiwa. Unsikhi upwa likhwisaya, khukhanya khukhadi ndukha.
Nígbà tí a ṣe ìtẹ̀bọmi àwọn ènìyàn gbogbo tán, ó sì ṣe, a bamitiisi Jesu pẹ̀lú, bí ó ti ń gbàdúrà, ọ̀run ṣí sílẹ̀,
22 Umepo Umbalache akhikha pakhanya pa mwene ikhwoni kya khivili vili kifane njiva, unsikhi gugugwa ilimenyu likhicha ukhuhuma khukhaya iyitu, “Uve mwana vango ugane, ndiganile ficho na yue.”
Ẹ̀mí Mímọ́ sì sọ̀kalẹ̀ sí orí rẹ̀ ní àwọ̀ àdàbà, ohùn kan sì ti ọ̀run wá, tí ó wí pé, “Ìwọ ni àyànfẹ́ ọmọ mi; ẹni tí inú mi dùn sí gidigidi.”
23 Pwu u Yisu yuywa avile tenguluve ukhumanyisya akhale ni miakha salasini. Ale mwana (nauvu yivalile) uva Yusufu, mwana va Eli,
Jesu tìkára rẹ̀ ń tó bí ẹni ọgbọ̀n ọdún, nígbà tí ó bẹ̀rẹ̀ iṣẹ́ ìránṣẹ́ rẹ̀ ó jẹ́ (bí a ti fi pè) ọmọ Josẹfu, tí í ṣe ọmọ Eli,
24 mwana va Mathati, mwana va Lawi, mwana wa Melki, mwana wa Yana, mwana wa Yusufu,
tí í ṣe ọmọ Mattati, tí í ṣe ọmọ Lefi, tí í ṣe ọmọ Meliki, tí í ṣe ọmọ Janai, tí í ṣe ọmọ Josẹfu,
25 Mwana va Mtathia, mwana va Amosi, mwana va Nahumu, mwana va Eli, mwana va Nagai,
tí í ṣe ọmọ Mattatia, tí í ṣe ọmọ Amosi, tí í ṣe ọmọ Naumu, tí í ṣe ọmọ Esili, tí í ṣe ọmọ Nagai,
26 mwana va Maati, mwana va Matathia, mwana va Semeini, mwana va Yusufu, mwana va Yuda,
tí í ṣe ọmọ Maati, tí í ṣe ọmọ Mattatia, tí í ṣe ọmọ Ṣimei, tí í ṣe ọmọ Josẹfu, tí í ṣe ọmọ Joda,
27 Mwana va Yoanani, mwana wa Resa, mwana wa Zeerubabeli, mwana va Shealtieli, mwana va Neri,
tí í ṣe ọmọ Joana, tí í ṣe ọmọ Resa, tí í ṣe ọmọ Serubbabeli, tí í ṣe ọmọ Ṣealitieli, tí í ṣe ọmọ Neri,
28 mwana va Melki, mwana va Adi, mwana va Kosamu, mwana va Elmadamu, mwana va Eri,
tí í ṣe ọmọ Meliki, tí í ṣe ọmọ Adi, tí í ṣe ọmọ Kosamu, tí í ṣe ọmọ Elmadamu, tí í ṣe ọmọ Eri,
29 mwana va Yoshua, mwana va Eliezeri, mwana va Yorimu, mwana va Matathi, mwana va Lawi,
tí í ṣe ọmọ Joṣua, tí í ṣe ọmọ Elieseri, tí í ṣe ọmọ Jorimu, tí í ṣe Mattati, tí í ṣe ọmọ Lefi,
30 mwana va Simeoni, mwana va Yuda, mwana va Yusufu, mwana va Yonamu, mwana va Eliyakimu,
tí í ṣe ọmọ Simeoni, tí í ṣe ọmọ Juda, tí í ṣe ọmọ Josẹfu, tí í ṣe ọmọ Jonamu, tí í ṣe ọmọ Eliakimu,
31 mwana va Melea, mwana va Mena, mwana va Matatha, mwana va Nathani, mwana va Daudi,
tí í ṣe ọmọ Melea, tí í ṣe ọmọ Menna, tí í ṣe ọmọ Mattata, tí í ṣe ọmọ Natani, tí í ṣe ọmọ Dafidi,
32 mwana va Yese, mwana va Obedi, mwana va Boazi, mwana va Salmoni, mwana va Nashoni,
tí í ṣe ọmọ Jese, tí í ṣe ọmọ Obedi, tí í ṣe ọmọ Boasi, tí í ṣe ọmọ Salmoni, tí í ṣe ọmọ Nahiṣoni,
33 mwana va Abinadabu, mwana va Aramu, mwana va Hesroni, mwana va Peresi, mwana va Yuda,
tí í ṣe ọmọ Amminadabu, tí í ṣe ọmọ Ramu, tí í ṣe ọmọ Hesroni, tí í ṣe ọmọ Peresi, tí í ṣe ọmọ Juda.
34 mwana va Yakobo, mwana va Isaka, mwana va Ibrahiumu, mwana va Tera, mwana va Nahori,
Tí í ṣe ọmọ Jakọbu, tí í ṣe ọmọ Isaaki, tí í ṣe ọmọ Abrahamu, tí í ṣe ọmọ Tẹra, tí í ṣe ọmọ Nahori,
35 mwana va Seruig, mwana va Ragau, mwana va Pelegi, mwana va Eberi, mwana va Sala,
tí í ṣe ọmọ Serugu, tí í ṣe ọmọ Reu, tí í ṣe ọmọ Pelegi, tí í ṣe ọmọ Eberi, tí í ṣe ọmọ Ṣela.
36 Mwana va Kenani, mwana va Arfaksadi, mwana va Shemu, mwana va Nuhu, mwana va Lameki,
Tí í ṣe ọmọ Kainani, tí í ṣe ọmọ Arfaksadi, tí í ṣe ọmọ Ṣemu, tí í ṣe ọmọ Noa, tí í ṣe ọmọ Lameki,
37 mwana va Methusela, mwana va Henoko, mwana va Yaredi, mwana va Mahalaleli, mwana wa Kenani,
tí í ṣe ọmọ Metusela, tí í ṣe ọmọ Enoku, tí í ṣe ọmọ Jaredi, tí í ṣe ọmọ Mahalaleli, tí í ṣe ọmọ Kainani.
38 mwana wa Enoshi, mwana va Sethi, mwana va Adamu, mwana va Nguluve.
Tí í ṣe ọmọ Enosi, tí í ṣe ọmọ Seti, tí í ṣe ọmọ Adamu, tí í ṣe ọmọ Ọlọ́run.