< Marakai 4 >
1 Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a anage hie, maka'zama refkoma hanua knamo'a, avenifima tevema hugre'nageno keonke zama tefizo nehiankna kna neankino, avufga rama nehia vahe'ene, kefo avu'ava'ma nehia vahe'enena, hagage trazama tevemo'ma tefanenema hiaza hugahie. Ana tevemo'a arafunama, azankuna'ma, maka'zama 'anena tefanane hugahie.
“Dájúdájú, ọjọ́ náà ń bọ̀; tí yóò máa jó bi iná ìléru. Gbogbo àwọn agbéraga, àti gbogbo àwọn olùṣe búburú yóò dàbí àgékù koríko: ọjọ́ náà tí ń bọ̀ yóò si jó wọn run,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “Ti ki yóò fi kù gbòǹgbò kan tàbí ẹ̀ka kan fún wọn.
2 Hianagi Nagri nagigu'ma koro'ma nehuta, nagoraga'ama nemaniza vahe'motarera, hanavenimo'a tamagrite'ma efore'ma haniana, fatgo avu'avaza zamo'a zagemo'ma hiaza huno remsa hunermanteno, tamazeri knamarena bulimakao anentamo'ma keginafinti'ma atiramino ne-eno muse huno haru huno takaure takaure huno vano hiankna hugahaze.
Ṣùgbọ́n fún ẹ̀yin tí ó bẹ̀rù orúkọ mi, oòrùn òdodo yóò yọ, pẹ̀lú ìmúláradá ni ìyẹ́ apá rẹ̀. Ẹ̀yin yóò sì jáde lọ, ẹ̀yin yóò sì máa fò fún ayọ̀ bi àwọn ẹgbọrọ màlúù tí a tú sílẹ̀ lórí ìso.
3 E'i ana knazupa kefo avu'ava'ma nehaza vahe zamagofetu tamagia reta vano hugahaze. Na'ankure e'i ana kna zupa ana vahe'mo'za tamagia agu'samofo fenka kaziga tanefa samparegahaze. E'i anazama fore'ma hania kna retro nehuankino ana zana fore hugahie huno Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a hu'ne.
Ẹ̀yin yóò sì tẹ àwọn ènìyàn búburú mọ́lẹ̀: nítorí wọn yóò di eérú lábẹ́ àtẹ́lẹsẹ̀ yín, ní ọjọ́ náà tí èmi yóò ṣe nǹkan wọ̀nyí,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
4 Eri'za vaheni'a Mosesema kasegema ami'noa zanku tamagesa antahiho. Maka kasegene tra kenema maka Israeli vahe'mo'zama avaririsaze hu'nama Sainai (Horep) agonafima ami'noa kasegene tra kenena tamagera okaniho.
“Ẹ rántí òfin Mose ìránṣẹ́ mi, àwọn ìlànà àti òfin èyí tí mo fún un ní Horebu fún gbogbo Israẹli.”
5 Hagi antahiho, Nagra kasnampa vaheni'a Elaizana huntanenkeno egota hutenigena, Ra Anumzamofo knama efore hanigeno ranra knazama efore huno vahe'ma zamazeri koro'ma hania kna henka egahie. (Luku 1:17)
“Wò ó, èmi yóò rán wòlíì Elijah sí i yín, ki ọjọ́ ńlá, ọjọ́ ẹ̀rù Olúwa to dé.
6 Agra zamafahe'ina zamagu'a eri rukrahe hanige'za mofavrezmire ne-enageno, mofavreramimofo zamagu'a eri arukrahe hanige'za zamafahe'intega vugahaze. Anama osnage'na Nagra e'na ama mopa emeri haviza hugahue.
Òun yóò sì pa ọkàn àwọn baba dà sí ti àwọn ọmọ, àti ọkàn àwọn ọmọ sì ti àwọn baba wọn, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, èmi yóò wá, èmi yóò sì fi ilẹ̀ náà gégùn.”