< Jasi Vahere 19 >
1 Hagi Israeli vahe'mofo kinima omani'nea knafina mago Livae nagapinti nera Efraemi agona kokampi mani'ne. Hagi ana ne'mo'a mago kna Juda mopafi vuno, Betlehemu kumateti nampa 2ara a'tampi ome avreno e'ne.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì Israẹli kò ní ọba. Ọ̀kan nínú àwọn ọmọ Lefi tí ń gbé ibi tí ó sá pamọ́ nínú àwọn agbègbè òkè Efraimu, mú àlè kan láti Bẹtilẹhẹmu ní Juda.
2 Hianagi ana a'mo'a mago'a vene'nene savari huteno, nevena atreno kuma'arega 4'a ika umani'ne.
Ṣùgbọ́n àlè rẹ̀ náà sì ṣe panṣágà sí i, òun fi sílẹ̀, ó sì padà lọ sí ilé baba rẹ̀ ní Bẹtilẹhẹmu ti Juda, ó sì wà ní ibẹ̀ ní ìwọ̀n oṣù mẹ́rin,
3 Ana'ma higeno'a neve'a nenaro arimpa omeri fru huno avreno enaku eri'za ne'ane, tare donki afu'ane nevreno vu'ne. Hagi ana kumate'ma uhanatigeno'a, ana ne'mofo nenaro'a avreno nefa nonte vigeno, nefa'a tusi muse nehuno avrente'ne.
ọkọ rẹ̀ lọ sí ibẹ̀ láti rọ̀ ọ́ pé kí ó padà sí ọ̀dọ̀ òun. Nígbà tí ó ń lọ ó mú ìránṣẹ́ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ méjì lọ́wọ́, obìnrin náà mú un wọ inú ilé baba rẹ̀ lọ, nígbà tí baba obìnrin náà rí i ó fi tayọ̀tayọ̀ gbà á.
4 Hagi ana ne'mofo nenemo'a osi'a manigenka vuo higeno, ana ne'mo'a nenemo nompina ne'zane tinena neneno 3'a kenage manino maseno hu'ne.
Àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà rọ̀ ọ́, ó sì borí rẹ̀ láti dá a dúró fún ìgbà díẹ̀, òun sì dúró fún ọjọ́ mẹ́ta, ó ń jẹ, ó ń mu, ó sì ń sùn níbẹ̀.
5 Hagi namba 4 knarera nanterame otino noma'arega vunaku keonke'zana retro hu'ne. Hianagi nenemo'a huno, Bretia netenka vugahane.
Ní ọjọ́ kẹrin, wọ́n dìde ní òwúrọ̀ kùtùkùtù òun sì múra láti padà lọ, ṣùgbọ́n baba ọmọbìnrin náà wí fún àna rẹ̀ pé, “Fi ohun jíjẹ díẹ̀ gbé inú ró nígbà náà kí ìwọ máa lọ.”
6 Anagema nenemo'a higeno'a ana netremokea ete manike ne'zane tinena ne'na'e. Ana ne'zama nenakeno'a nenemo'a otiazamo amanage hu'ne, Muse hugantoanki mago kenage'ene maseneta ne'zana neneta musena huteta vi'o.
Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jókòó láti jọ jẹun àti láti jọ mu. Lẹ́yìn èyí ni baba ọmọbìnrin wí pé, “Jọ̀wọ́ dúró ní alẹ́ yìí kí o sì gbádùn ara rẹ.”
7 Hianagi Livae ne'mo'a vunaku keonke'zama'a enerino otigeno, nenemo'a tutu huno, Mago kenagera masetenka vuo, higeno mase'ne.
Nígbà tí ọkùnrin náà dìde láti máa lọ, baba ìyàwó rẹ̀ rọ̀ ọ́, torí náà ó sùn níbẹ̀ ní alẹ́ ọjọ́ náà.
8 Hagi maseno namba 5fu knarera nanterame otino vunaku retrotra higeno, nenemo'a otiazamo amanage hu'ne, ne'zana krenka nenenka mani'negeno kinagasena vuo, huno higeke ete mago knane mani'neke ne'zana kreke ne'na'e.
Ní òwúrọ̀ ọjọ́ karùn-ún nígbà tí ó dìde láti lọ, baba ọmọbìnrin wí pé, “Fi oúnjẹ gbé ara ró. Dúró de ọ̀sán!” Àwọn méjèèjì sì jùmọ̀ jọ jẹun.
9 Hagi ana'ma hute'za agrama, nenaro'ma eri'za ne'ama hu'za vunaku tro hu'za oti'zageno, ana a'mofo nefa'a amanage hu'ne, Keho, hago kinagaseanki, meni kenage'enena maseta musena huteta, okina nanterame otita vugahaze.
Nígbà tí ọkùnrin náà, pẹ̀lú àlè àti ìránṣẹ́ rẹ̀, dìde láti máa lọ, àna rẹ̀, baba ọmọbìnrin náà ní, “Wò ó ilẹ̀ ti ń ṣú lọ, dúró níbí, ọjọ́ ti lọ. Dúró kí o sì gbádùn ara rẹ. Ìwọ lè jí ní àárọ̀ kùtùkùtù ọ̀la kí ìwọ sì máa lọ ilé.”
10 Hianagi ana ne'mo'a ru'enema masezankura avesra nehuno, donki afutrema'amofo agumpi mani'noma vu'zana retro hunenteno, nenaronena nevreno Jebusi kumakura menina e'i Jerusalemie nehazankino ana kantega vu'ne.
Ṣùgbọ́n nítorí pé òun kò fẹ́ dúró mọ́ níbẹ̀ ní òru náà ọkùnrin náà kúrò ó sì gba ọ̀nà Jebusi: ọ̀nà Jerusalẹmu pẹ̀lú àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ méjèèjì tí ó fi dì í ní gàárì àti àlè rẹ̀.
11 Hagi Jebusi kumate'ma azageno'a kinagasegeno, eri'za ne'amo'a amanage hu'ne. Jebusi vahe ran kumapi umasenune.
Nígbà tí wọ́n súnmọ́ Jebusi tí ilẹ̀ ti fẹ́ ṣú tan, ìránṣẹ́ náà sọ fún ọ̀gá rẹ̀ pé, “Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a dúró ní ìlú yìí tí í ṣe ti àwọn ará Jebusi kí a sì sùn níbẹ̀.”
12 Anagema higeno'a kva'amo'a amanage hu'ne, Ru vahe kumapina Israeli vahe'ma omani'nesia kumapina uomasegosunanki, nevuta Gibea uhanatigahune.
Ọ̀gá rẹ̀ dá a lóhùn pé, “Rárá o, àwa kì yóò wọ ìlú àwọn àjèjì, àwọn tí olùgbé ibẹ̀ kì í ṣe ọmọ Israẹli, a yóò dé Gibeah.”
13 Anage nehuno ana nehaza nera amanage huno asami'ne. Enketa ko nevuta Gibea kumatero Rama kumatero umasamneno.
Ó fi kún un pé, ẹ wá ẹ jẹ́ kí a gbìyànjú kí a dé Gibeah tàbí Rama kí a sùn ní ọ̀kan nínú wọn.
14 E'i anage nehu'za vuvava hu'za Benzameni naga'mofo mopafi Gibea kuma tava'onte uhanati'zageno zagemo'a uramige'za,
Wọ́n sì tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò wọn, oòrùn wọ̀ bí wọ́n ti súnmọ́ Gibeah tí ṣe ti àwọn Benjamini.
15 ana kumapi masenaku kuma amu'nompi umani'nazanagi, mago vahe'mo'a zamavare nompina ontege'za mani'nazageno,
Wọ́n yípadà wọ́n lọ sí inú ìlú Gibeah láti wọ̀ síbẹ̀ ní òru náà, wọ́n lọ wọ́n sì jókòó níbi gbọ̀ngàn ìlú náà, ṣùgbọ́n kò sí ẹni tí ó gbà wọ́n sínú ilé rẹ̀ láti wọ̀ sí.
16 mago ranafamo hoza'aregatira kinaga e'ne. Ana nera Efraemi agona kokampinti ne' Benzameni naga'ene Gibea kumate zoka emani'nea nere.
Ní alẹ́ ọjọ́ náà ọkùnrin arúgbó kan láti àwọn òkè Efraimu, ṣùgbọ́n tí ń gbé ní Gibeah (ibẹ̀ ni àwọn ẹ̀yà Benjamini ń gbé) ń ti ibi iṣẹ́ rẹ̀ bọ̀ láti inú oko.
17 Hagi ana ranafa ne'mo'ma ne-eno'ma eme kesaga huno keama ana naga'ma kuma amu'nompima mani'nazageno'a anage huno zamantahige'ne, Igati e'neta iga vunaku emani'naze?
Nígbà tí ó wòkè ó rí arìnrìn-àjò náà ní gbọ̀ngàn ìlú náà, ọkùnrin arúgbó yìí bi í léèrè pé, “Níbo ni ò ń lọ? Níbo ni o ti ń bọ̀?”
18 Higeno ana ne'mo'a amanage huno hu'ne, Efraemi agona kokampi kumanirega vunaku Juda kaziga Betlehemu kumateti eta emani'nonanagi, vahe'mo'za nozamifina tavreontazageta mani'none.
Ọmọ Lefi náà dá a lóhùn pé, “Bẹtilẹhẹmu ti Juda ni àwa ti ń bọ̀, àwa sì ń lọ sí agbègbè tí ó sá pamọ́ ní àwọn òkè Efraimu níbi ti mo ń gbé. Mo ti lọ sí Bẹtilẹhẹmu ti Juda, èmi sì ń lọ sí ilé Olúwa nísinsin yìí. Kò sí ẹni tí ó gbà mí sí ilé rẹ̀.
19 Hagi donkitimofo ne'zane, nagrama nesua wainine bretine, a'nimofo ne'zane eri'za vahe'nimofo ne'zanena eri'nonankita mago zankura upara osu'none.
Àwa ní koríko àti oúnjẹ tó tó fún àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ wa àti oúnjẹ àti wáìnì fún àwa ìránṣẹ́ rẹ—èmi, ìránṣẹ́bìnrin rẹ àti ọ̀dọ́mọkùnrin tí ó wà pẹ̀lú wa. A ò ṣe aláìní ohun kankan.”
20 Anage'ma hazageno'a ana ranafa ne'mo'a amanage hu'ne, knarekita nagri nontega vanage'na maka'mota kegava huramantegahue. Hianagi amafina omasegahaze.
Ọkùnrin arúgbó náà sì wí pé. “Àlàáfíà fún ọ, bí ó ti wù kí ó rí, èmi yóò pèsè gbogbo ohun tí o nílò, kìkì pé kí ìwọ má ṣe sun ní ìgboro.”
21 Anage nehuno zamavareno noma'afi vuno donkizmimofo ne'zana nezamige'za zamagra zamaga ome sese hute'za ne'zane tinena ne'naze.
Òun sì mú wa sí ilé rẹ̀, ó ń bọ́ àwọn kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀. Lẹ́yìn ìgbà tí wọ́n ti wẹ ẹsẹ̀ wọn, àwọn àlejò náà jẹ, wọ́n mu.
22 Hagi ne'zama nene'za musema nehazageno'a, ana kumapi'ma hazenkema nehaza vene'nemo'za anama mani'naza nona eme avazagigagiza kafantera vagare vagare hu'za nemasagiza, ana ranafagura amanage hu'naze, E'ima nonka'afima avrente'nana nera avreramigeta monko zana huntamneno.
Ǹjẹ́ bí wọ́n ti ń ṣe àríyá, kíyèsi i, àwọn ọkùnrin ìlú náà, àwọn ọmọ Beliali kan, yí ilé náà ká, wọ́n sì ń lu ìlẹ̀kùn; wọ́n sì sọ fún baálé ilé náà ọkùnrin arúgbó náà pé, “Mú ọkùnrin tí ó wọ̀ sínú ilé rẹ wá, kí àwa lè mọ̀ ọ́n.”
23 Hagi ana ranafamo'a atiramiazamo amanage huno zamasami'ne, Nafuheta, amanahu kefo avu'ava zana osiho. Na'ankure ama ne'mo'a ko noniafi emani'ne.
Ọkùnrin, baálé ilé náà sì jáde tọ̀ wọ́n lọ, ó sì wí fún un pé, “Bẹ́ẹ̀ kọ́ ẹ̀yin arákùnrin mi, èmi bẹ̀ yín, ẹ má ṣe hùwà búburú; nítorí tí ọkùnrin yìí ti wọ ilé mi, ẹ má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí.
24 Hagi keho, vene omase mofani'ane ana ne'mofo a'enena ama mani'na'anki zanavreta vuta nazano huzanante'naku'ma hanaza zana ome huznanteho. Hianagi ama ne'mofona kefo avu'avara huonteho.
Kíyèsi i, ọmọbìnrin mi ni èyí, wúńdíá, àti àlè rẹ̀; àwọn ni èmi ó mú jáde wá nísinsin yìí, kí ẹ̀yin tẹ̀ wọ́n lógo, kí ẹ̀yin ṣe sí wọn bí ó ti tọ́ lójú yín: ṣùgbọ́n ọkùnrin yìí ni kí ẹ̀yin má ṣe hùwà òmùgọ̀ yìí sí.”
25 Hianagi ana vene'neramimo'za ke'a ontahizageno, Livae ne'mo'a nenarona kaha anagino retufezamige'za ana vene'nemo'za ana ara monkozana hunte'za azeri haviza hu'za vano nehazageno kotige'za atrazageno e'ne.
Ṣùgbọ́n àwọn ọkùnrin náà kò fetí sí tirẹ̀. Nítorí náà ọkùnrin náà mú àlè rẹ̀ ó sì tari rẹ̀ jáde sí wọn, wọ́n sì bá a fi ipá lòpọ̀, wọ́n sì fi gbogbo òru náà bá a lòpọ̀, nígbà tí ó di àfẹ̀mọ́júmọ́ wọ́n jọ̀wọ́ rẹ̀ lọ́.
26 Hagi ana a'mo'a eazamo neve'ma mase'nea nomofo kahante eme traka huno mase'negeno rumasa hu'ne.
Nígbà tí ojúmọ́ bẹ̀rẹ̀ sí là obìnrin náà padà lọ sí ilé tí ọ̀gá rẹ̀ wà, ó ṣubú lulẹ̀ lọ́nà, ó sì wà níbẹ̀ títí ó fi di òwúrọ̀.
27 Hagi neve'ma vunaku'ma nanterama otino'ma kafama anagiana nenaro'a, kaha tra zafare azeriteno mase'negeno negeno anage hu'ne,
Nígbà tí ọ̀gá rẹ̀ jí tí ó sì dìde ní òwúrọ̀ tí ó sì ṣí ìlẹ̀kùn ilé náà, tí ó sì bọ́ sí òde láti tẹ̀síwájú nínú ìrìnàjò rẹ̀, kíyèsi i àlè rẹ̀ wà ní ṣíṣubú ní iwájú ilé, tí ọwọ́ rẹ̀ sì di òpó ẹnu-ọ̀nà ibẹ̀ mú,
28 otigeta havamneno. Hianagi ana a'mo'a kea osigeno donki afu'amofo agumpi avufga'a erinteno noma'arega vu'ne.
òun sì wí fún obìnrin náà pé, “Dìde jẹ́ kí a máa bá ọ̀nà wa lọ.” Ṣùgbọ́n òun kò dá a lóhùn. Nígbà náà ni ọkùnrin náà gbé e lé orí kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀, ó sì kọjá lọ sí ilé e rẹ̀.
29 Hagi ana ne'mo'ma noma'arema uhanatino'a, kazi erino ana ara 12fu'afi taga huteno, 12fu'a Israeli naga'nofi'ma mani'nazarega mago mago huno ana a'mofo avufga atregeno vuno eno hu'ne.
Nígbà tí ó dé ilé, ó mú ọ̀bẹ ó sì gé àlè rẹ̀ ní oríkeríke sí ọ̀nà méjìlá, ó sì fi wọ́n ránṣẹ́ sí gbogbo agbègbè Israẹli.
30 Hagi ana zama kaza vahe'mo'za amanage hu'naze, Isipiti'ma e'nona knareti'ma eno ama knare'ma ehanatiana Israeli vahe'mota amanahu kefo hazenkezana onke'nonaza fore hianki, ama ana zankura na'ane huta tamagesa antahize?
Gbogbo ẹni tí ó rí i sì wí pé, “A kò ti rí i, bẹ́ẹ̀ a kò tí ì ṣe irú nǹkan yìí rí, kì í ṣe láti ọjọ́ tí Israẹli ti jáde tí Ejibiti wá títí di òní olónìí. Ẹ rò ó wò, ẹ gbìmọ̀ràn, kí ẹ sọ fún wa ohun tí a yóò ṣe!”