< Zeremaia 19 >

1 Ra Anumzamo'a amanage huno nasami'ne. Mopa kavoma tro nehia netega uraminka, mopa kavoa mago ome miza huo. Ana hutenka mago'a kva vahe'ene pristi vahe'enena kea hunka zamavare'nenka vuo.
Èyí ní ohun tí Olúwa wí: “Lọ ra ìkòkò lọ́dọ̀ alámọ̀, mú dání lára àwọn àgbàgbà ọkùnrin àti wòlíì.
2 Hagi Jerusalemi kuma'mofona, kavo rurakohu kafanema nehaza kafanteti atiramita vuta Ben-Hinomu agupofi viho. Anantegama vuteta amanage hunka ome zamasamio.
Kí o sì lọ sí àfonífojì ọmọ Beni-Hinnomu, níwájú ẹnu ibodè Harsiti, níbẹ̀ ni kí o sì kéde gbogbo ọ̀rọ̀ tí èmi yóò sọ fún ọ.
3 Tamagra Juda kini vahe'motane Jerusalemi kumapima nemaniza vahe'motanena Ra Anumzamo'ma hiankea antahiho, Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzana, Israeli vahe'mokizmi Anumzamo'a amanage hie, antahiho Nagra rama'a knaza avre'na ama agupofina esuge'za ana zamofo agenkema vahe'mo'za nentahisu'za antri hugahaze.
Kí o sì wí pé, ‘Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa ẹ̀yin ọba àwọn Juda àti ẹ̀yin ará Jerusalẹmu. Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli sọ. Dẹtí sí mi! Èmi yóò mú ìparun wá síbí, etí gbogbo wọn tó bá gbọ́ ọ yóò hó yaya.
4 Na'ankure Israeli vahe'mo'za zamefi hunenami'za ama agupofina ru anumzamofo mono hunte kuma eri fore hu'naze. Ana nehu'za Juda kini vahe'mo'zane, zamagehe'zane zamagranena ke'za antahi'za osu'naza havi anumzante mananentake'za insensia kre mana vu'naze. Ana nehu'za ke'zami omane mofavre nagara rama'a zamahe'za anampina korana eri tagi atre'naze.
Nítorí wọ́n ti gbàgbé mi, wọ́n sì ti sọ ibí di ilé fún òrìṣà àjèjì; wọ́n ti sun ẹbọ nínú rẹ̀ fún òrìṣà tí àwọn baba wọn tàbí tí ọba Juda kò mọ̀ rí, wọ́n ti fi ẹ̀jẹ̀ aláìṣẹ̀ kún ilẹ̀ yìí.
5 Ana nehu'za zamagra Bali havi anumzante'ma mono'ma huntesaza kumatami tro huntesga hu'ne'za, ne' mofavre'zamia zamahe'za Bali havi anumzantega tevefi kre fanenehu ofa nehaze. Nagra kea huramante'na, e'ina hiho hu'na huozamante'noa avu'avaza nehu'za, Nagri antahi'zampinena e'inahu antahi'zana omane'neaza tro hu'naze.
Wọ́n ti kọ́ ibi gíga fún Baali láti sun ọmọkùnrin wọn gẹ́gẹ́ bí ohun ẹbọ sísun sí Baali—èyí tí èmi kò pàṣẹ láti ṣe, tí èmi kò sì sọ, tàbí tí kò sì ru sókè láti inú ọkàn mi.
6 E'ina hu'negu antahiho, Ra Anumzamo'a huno mago kna ne-eanki'za ama mopagura Tofeti agupoe nehu'za, Ben-Hinomu agupoe hu'za osugahazanki, vahe zamahe'za rukitagi netraza agupoe hu'za hugahaze.
Nítorí náà ṣọ́ra ọjọ́ ń bọ̀ ni Olúwa wí nígbà tí àwọn ènìyàn kì yóò pe ibí ní Tofeti mọ́ tàbí àfonífojì ọmọ Hinnomu, ṣùgbọ́n àfonífojì Ìpakúpa.
7 Tamagra Jerusalemi vahe'motane Juda vahe'motanena rama'a antahintahi retro hugahaze. Hianagi nagra ama agupofi ana antahintahi zana eri haviza hugahue. Nagra ha' vahetamia zamatresanuge'za e'za bainati kazinteti eme tamahe frigahaze. Ana hutesage'na namaramine afi zagagafarami huzmante'sanuge'za e'za fri tamavufga eme traga hu'za negahaze.
“‘Ní ibí yìí ni èmi yóò ti pa èrò Juda àti Jerusalẹmu run. Èmí yóò mú wọn ṣubú nípa idà níwájú àwọn ọ̀tá wọn, lọ́wọ́ àwọn tí ó ń wá ẹ̀mí wọn. Èmi yóò sì fi òkú wọn ṣe oúnjẹ fún àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run àti ẹranko ilẹ̀.
8 Nagra ana hanugeno Jerusalemi kumamo'a haviza huno me'nesige'za, kantegama vanoma hanaza vahe'mo'za anazama nege'za antri nehu'za zamagogogu hugahaze. Na'ankure rama'a hazenke'zamo'ma enoma emeri havizama hu'nea zanku anara hugahaze.
Èmi yóò sọ ìlú yìí di ahoro àti ohun ẹ̀gàn, gbogbo àwọn tí ń kọjá yóò bẹ̀rù wọn yóò sì máa fòyà nítorí gbogbo ọgbẹ́ rẹ̀.
9 Hagi ha' vahe'mo'zama eme ha'ma huramantenaku'ma esu'za Jerusalemi kumara eme avazagi kagigahaze. Ana hanageno ne'zana vagaresanigeta ne'zama nesaza zanku hugeta tamagri tava'onte'ma nemanisaza vahera zamaheta neneta, ne'mofavre nagataminena zamaheta negahaze.
Èmi yóò mú kí wọ́n jẹ ẹran-ara ọmọ wọn ọkùnrin àti ẹran-ara ọmọ wọn obìnrin, ẹnìkínní yóò sì jẹ ẹran-ara ẹnìkejì, nígbà ìdótì àti ìhámọ́ láti ọwọ́ ọ̀tá wọn, àti àwọn tí ó ń wá ẹ̀mí wọn.’
10 Jeremaiaga nanekema huvagama nerenka, kagranema vu'naza vahe'mo'za negesagenka mopa kavoma erinka vu'nana kavoa rurako nehunka,
“Nígbà náà ni ìwọ yóò fọ́ ìkòkò náà ní ojú àwọn tí ó bá ọ lọ.
11 amanage hunka zamasamio, Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzamo'a huno, ama mopa kavoma ete eri so'e osu'are'ma rufuzafupeaza hu'na, Juda vahe'ene Jerusalemi kumapima nemaniza vahe'enena zamazeri haviza hugahue. Ana hanugeno Tofeti mopa'afina frisaza vahe'ma asezamantesaza mati megahie. Hianagi rama'a vahe friga hazankino vahe'ma ase zamantesaza kankamuna omanegahie.
Kí o sì sọ fún wọn pé, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. Èmi a fọ́ orílẹ̀-èdè yìí àti ìlú yìí gẹ́gẹ́ bí ìkòkò amọ̀ yìí ṣe fọ́ tí kò sì ní sí àtúnṣe. Wọn a sì sin àwọn òkú sí Tofeti títí tí kò fi ní sí ààyè mọ́.
12 Nagra Ra Anumzamo'na huanki'na, ama ran kuma'ene anampima nemaniza vahe'enena e'inahu avu'ava huna zamazeri haviza hugahue. Ana nehu'na Nagra ama ran kumara eri haviza hutresanugeno Tofeti mopamo'ma hu'neaza huno agru osugahie.
Èyí ni ohun tí èmi yóò ṣe sí ibí yìí àti àwọn tí ń gbé ní ibí yìí ni Olúwa wí. Èmi yóò mú ìlú yìí dàbí Tofeti.
13 Jerusalemi kumapima me'nea nontamine Juda kini vahe'mokizmi nontamimo'za, Tofeti mopamo'ma hiaza hu'za Nagri navurera agrua osugahaze. Na'ankure ana nontamimofo agofetura marerita monafima me'nea hanafitaminte, mananentake'za insensia kre mna nevuta, kaza osu havi anumzantamintera waini tina tagita ofa hu'naze.
Àwọn ilé tí ó wà ní Jerusalẹmu àti ti ọba ìlú Juda ni a ó sọ di àìmọ́ bí Tofeti, gbogbo ilé tí wọ́n ti ń sun tùràrí ni orí òrùlé sí gbogbo ogun ọ̀run, tí a sì ń rú ẹbọ mímu sí ọlọ́run mìíràn.’”
14 Hagi Ra Anumzamo'a hunantege'na Tofetima mani'nena kasnampa nanekema nehuretira nagra atrena vu'na Ra Anumzamofo mono nomofo kumapi ome oti'nena amanage huna vahera zamasami'noe.
Jeremiah sì padà láti Tofeti níbi tí Olúwa rán an sí láti sọ àsọtẹ́lẹ̀ ó sì dúró ní gbangba tẹmpili Olúwa, ó sì sọ fún gbogbo ènìyàn pé,
15 Monafi sondia vahe'mofo Ra Anumzama Israeli vahe Anumzamo'a huno, amama me'nea ran kumate'ene ne'onse kumatamima megagi'nea kumatamintera, huvempama hu'noa knazantamina kofa'a knafi atrenugeno egahie. Na'ankure tamagrira tamagu'amo'a hankavenetigeta Nagri nanekea ontahi'naze.
“Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí: ‘Tẹ́tí sílẹ̀! Èmi yóò mú ìdààmú tí mo ti sọ àsọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ bá ìlú yìí àti ìgbèríko tí ó yí i ká, nítorí ọlọ́rùn líle ni wọ́n, wọn kò si ní fẹ́ fetí sí ọ̀rọ̀ mi.’”

< Zeremaia 19 >