< Jenesis 2 >

1 E'inahu huno monane mopane, anampima me'nea zantamina maka trohu vagare'ne.
Báyìí ni Ọlọ́run parí dídá àwọn ọ̀run àti ayé, àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀.
2 Eri'za eri vagareteno, nampa 7ni knarera Anumzamo'a manigasa hu'ne.
Ní ọjọ́ keje Ọlọ́run sì parí iṣẹ́ rẹ̀ tí ó ti ń ṣe; ó sì sinmi ní ọjọ́ keje kúrò nínú iṣẹ́ rẹ̀ gbogbo tí ó ti ń ṣe.
3 Anumzamo'a nampa 7ni knarera manigasa nehuno, ana kna eri ruotge huno asomu hunte'ne. Na'ankure miko'a eri'zana eri vagarenegu huno manigasa hu'ne.
Ọlọ́run sì súre fún ọjọ́ keje, ó sì yà á sí mímọ́, nítorí pé ní ọjọ́ náà ni ó sinmi kúrò nínú iṣẹ́ dídá ayé tí ó ti ń ṣe.
4 Ra Anumzamo'ma monane mopane eri fore'ma hunte'nea nanekea, amanahu me'ne.
Èyí ni ìtàn bí Ọlọ́run ṣe dá àwọn ọ̀run àti ayé nígbà tí ó dá wọn. Nígbà tí Olúwa Ọlọ́run dá ayé àti àwọn ọ̀run.
5 E'i ana knafina za'ara zana fore ama mopafina osu'ne, na'ankure Ra Anumzamo'a ana knafina kora atregeno oru'ne. Ana higeno eri'za eri vahera fore huno omani'negeno,
Kò sí igi igbó kan ní orí ilẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni kò sí ewéko igbó kan tí ó tí ì hù jáde ní ilẹ̀, nítorí Olúwa Ọlọ́run kò tí ì rọ̀jò sórí ilẹ̀, kò sì sí ènìyàn láti ro ilẹ̀.
6 kampu'i tintamimo'za mopafinti hanati'za mika mopamofona tina ami'naze.
Ṣùgbọ́n ìsun omi ń jáde láti ilẹ̀, ó sì ń bu omi rin gbogbo ilẹ̀.
7 Ra Anumzamo'a kugusopa erino regripeteno vahe tro huno agonagampi Agra'a asimu'a huhu huvazigeno, vahe efore hu'ne.
Olúwa Ọlọ́run sì fi erùpẹ̀ ilẹ̀ mọ ènìyàn, ó si mí èémí ìyè sí ihò imú rẹ̀, ènìyàn sì di alààyè ọkàn.
8 Hanki Ra Anumzamo'a mago hoza zage hanati kaziga ante'neankino, ana hozagura Ideni hoze hu'nea hozamofo agu'afi, ana nera avreno ome ante'ne.
Olúwa Ọlọ́run sì gbin ọgbà kan sí Edeni ní ìhà ìlà-oòrùn, níbẹ̀ ni ó fi ọkùnrin náà tí ó ti dá sí.
9 Ra Anumzamo'a rumofo rumofo zafa higeno, mopafinti hage'ne. Hakare zafamo'za zamuma kete'ene ne'zama ne'arera knare hu'naze. Hagi ana hoza amu'nompina tare zafa me'ne. Mago zafa ofri manivava hu zafe. Hagi mago zafa knare zanki, havizanki huno'ma antahino keno'ma hu zafe.
Olúwa Ọlọ́run sì mú kí onírúurú igi hù jáde láti inú ilẹ̀, àwọn igi tí ó dùn ún wò lójú, tí ó sì dára fún oúnjẹ. Ní àárín ọgbà náà ni igi ìyè àti igi tí ń mú ènìyàn mọ rere àti búburú wà.
10 Hagi Ideni hozafintira mago ti hanatino enevuno, hozafina tina nemino ana timo'a refko huno 4'afi ranti evu'ne.
Odò kan sì ń ti Edeni sàn wá láti bu omi rin ọgbà náà, láti ibẹ̀ ni odò náà gbé ya sí ipa mẹ́rin.
11 Ese'ma evu'nea timofo agi'a Pisoni tinkino, maka Havira mopafi rugagino evu'ne. Ana mopafina knare goli me'ne.
Orúkọ èkínní ni Pisoni, òun ni ó sàn yí gbogbo ilẹ̀ Hafila ká, níbi tí wúrà gbé wà.
12 Ana mopafima me'neana mago'zana ruokamre knare goline, mana nentake'zane, mizama'amo mareri'nea oniksie nehaza havene me'ne.
(Wúrà ilẹ̀ náà dára, òjìá àti òkúta óníkìsì oníyebíye wà níbẹ̀ pẹ̀lú).
13 Anante timofo agi'a Gihoni tinkino, Kusi mopafi rugagino evu'ne.
Orúkọ odò kejì ni Gihoni, òun ni ó sàn yí gbogbo ilẹ̀ Kuṣi ká.
14 Hagi nampa 3a Taigrisi tinkino, zage hanati kaziga Asiria mopafi evu'ne. Hagi nampa 4a Yufretis tine.
Orúkọ odò kẹta ni Tigirisi, òun ni ó sàn ní apá ìlà-oòrùn ilẹ̀ Asiria. Odò kẹrin ni Eufurate.
15 Hanki Ra Anumzamo'a ana ne'ma avreno Ideni hozafima ante'neana, hoza eri'zama enerino kegavama hanigure huno avrente'ne.
Olúwa Ọlọ́run mú ọkùnrin náà sínú ọgbà Edeni láti máa ṣe iṣẹ́ níbẹ̀, kí ó sì máa ṣe ìtọ́jú rẹ̀.
16 Hianagi Ra Anumzamo'a amanage huno kasegea hunagru hunte'ne, Kagra mika hozafima me'nea zafa raga amne negahane.
Olúwa Ọlọ́run sì pàṣẹ fún ọkùnrin náà pé, “Ìwọ lè jẹ lára èyíkéyìí èso àwọn igi inú ọgbà;
17 Hianagi knare'zanki havi'zanki huno antahino keno'ma hu zafa raga onetfa huo. Hanki kagrama ana zafa ragama nesnanana, tamage hunka anazupa frigahane.
ṣùgbọ́n ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ nínú èso igi ìmọ̀ rere àti èso igi ìmọ̀ búburú, nítorí ní ọjọ́ tí ìwọ bá jẹ ẹ́ ni ìwọ yóò kùú.”
18 Hagi anante Ra Anumzamo'a anage hu'ne, Vemo'ma agrake maniazamo'a knare osianki'na, azahu vahera tro hanugeno knare hu'ne tragote'ne manigaha'e.
Olúwa Ọlọ́run wí pé, “Kò dára kí ọkùnrin wà ní òun nìkan. Èmi yóò ṣe olùrànlọ́wọ́ tí ó rí bí i rẹ̀ fún un.”
19 Nehuno mopa kateno mika zagagafane, namaramine, ne'one zagagafaraminena tro huzmanteteno zamavareno zamagi antezamisie huno ana nete vigeno, zamagi'a ante'zamigeno ana zamagima ante'nere me'ne.
Lẹ́yìn tí Olúwa Ọlọ́run ti dá àwọn ẹranko inú igbó àti gbogbo ẹyẹ ojú ọ̀run láti inú erùpẹ̀ ilẹ̀. Ó sì kó wọn tọ ọkùnrin náà wá láti wo orúkọ tí yóò sọ wọ́n; orúkọ tí ó sì sọ gbogbo ẹ̀dá alààyè náà ni wọ́n ń jẹ́.
20 Higeno ana ne'mo'a mika nontegama nemaniza zagagafagi, monafima hare'za vanoma nehaza nama'zagagi, mopafima nemaniza maka afi zagagafagi huno zamagi zami'neanagi, agri'ma azahu knampa'a omani'ne.
Gbogbo ohun ọ̀sìn, ẹyẹ ojú ọ̀run àti gbogbo ẹranko igbó ni ọkùnrin náà sọ ní orúkọ. Ṣùgbọ́n fún Adamu ni a kò rí olùrànlọ́wọ́ tí ó rí bí i rẹ̀.
21 Ana higeno Ra Anumzamo'a ve mofona azeri avukoko higeno mase himre'negeno, magoke omete asoza'a avazu huteno, avufanu renkanirente'ne.
Nígbà náà ni Olúwa Ọlọ́run mú kí ọkùnrin náà sùn fọnfọn; nígbà tí ó sì ń sùn, Ọlọ́run yọ egungun ìhà rẹ̀ kan, ó sì fi ẹran-ara bò ó padà.
22 Ra Anumzamo'a ana ne'mofo asoza'ama eri'nereti a' trohuno avreno egeno,
Olúwa Ọlọ́run sì dá obìnrin láti inú egungun tí ó yọ ní ìhà ọkùnrin náà, Ó sì mu obìnrin náà tọ̀ ọ́ wá.
23 ana ne'mo'a huno, Ha e'ine! Nagri zaferinareti zaferina'a tro nehuno, nagri navufareti avufga'a tro hu'neanki'na, are hu'na agi antemue. Na'ankure e'i ve'mofo avufafinti erino trohu'negu hu'ne.
Ọkùnrin náà sì wí pé, “Èyí ni egungun láti inú egungun mi àti ẹran-ara nínú ẹran-ara mi; ‘obìnrin’ ni a ó máa pè é, nítorí a mú un jáde láti ara ọkùnrin.”
24 E'i ana agafare vemo'a nererane, nefanena atreno, a'ane hagerafino eri mago huke nemani'e.
Nítorí ìdí èyí, ọkùnrin yóò fi baba àti ìyá rẹ̀ sílẹ̀, yóò sì dàpọ̀ mọ́ aya rẹ̀, wọn yóò sì di ara kan.
25 Zanagra arave huke kena omasi zanavufga zanavapa manina'anagi, zanagazea osu'ne.
Ọkùnrin náà àti aya rẹ̀ sì wà ní ìhòhò, ojú kò sì tì wọ́n.

< Jenesis 2 >