< Izikeli 11 >

1 Hagi anante Ra Anumzamofo Avamumo'a navresga huno mono nomofo zage hanati kazigama avugosama hunte'nea kafante vige'na koana, kafantera 25'a vene'ne mani'nazage'na zamage'noe. Hagi ana vene'nemofo amu'nompina kva netrena Asuri nemofo Ja'azania'ene, Benaia nemofo Pelatiakea otinake'na zanage'noe.
Ẹ̀mí sì gbé mi sókè, ó mú mi lọ sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa èyí tó dojúkọ ìlà-oòrùn. Ní àbáwọlé ẹnu-ọ̀nà yìí ni àwọn ọkùnrin mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n wá, mo rí Jaaṣaniah ọmọ Assuri àti Pelatiah ọmọ Benaiah, tí wọ́n jẹ́ ìjòyè àwọn ènìyàn.
2 Hagi Ra Anumzamo'a amanage huno nasmi'ne, Vahe'mofo mofavremoka antahio, ama ana venenemo'za rankumapina kefo avu'ava'ma hu antahintahia retro nehu'za, vahe'mokizmia kefo antahi'zana zami'naze.
Olúwa sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, àwọn ọkùnrin yìí ló ń pète ibi, wọ́n sì ń gbé ìmọ̀ràn búburú kalẹ̀ nínú ìlú.
3 Hagi zamagra amanage hu'za nehaze, nontamima ki kna zahufa erava'o osu'ne. Hagi rankuma'mo'a ne'zankre kavogna higeta, tagra ana kavofi afu ame'a meaza huta knare huta manigahune hu'za nehaze.
Wọ́n ní, ‘Kò ha tí ì tó àsìkò láti kọ́lé? Ìlú yìí ni ìkòkò ìdáná, àwa sì ni ẹran’.
4 E'ina hu'negu vahe'mofo mofavremoka kasnampa kea hunka huhaviza huzamanto.
Nítorí náà sọtẹ́lẹ̀ nípa wọn; ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀.”
5 Higeno Ra Anumzamofo Avamumo'a nagrite eno amanage huno eme nasmi'ne, Ra Anumzamo'a amanage huno hu'ne, Israeli vahemota tamagrama antahintahima nehaza zana Nagra ko kena antahina hu'noe huno nehie.
Ẹ̀mí Olúwa sì bà lé mi, ó sì wí pé, “Sọ̀rọ̀!” Báyìí ni Olúwa wí, ohun tí ẹ ń sọ nìyìí, ilé Israẹli, mo mọ ohun tó wà lọ́kàn yín.
6 Hagi tamagra rama'a vahe zamahe frizageno, mika kuma kantamimpina fri vahe'mokizmi zamavufagamo avite.
Ẹ̀yin ti sọ òkú yín di púpọ̀ nínú ìlú yìí, òkú sì ti kún gbogbo ìgboro rẹ̀.
7 E'ina hu'negu Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, rankumapima vahe'ma zamaheta zamavufagama eritruma hazana, e'i ame'a megeno rankumamo'a kavo me'ne. Hianagi tamagrira rankumapintira tamavaririnugeta atreta atiramigahaze.
“Torí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, àwọn òkú tí ẹ fọn sílẹ̀ sí àárín yín ni ẹran, ìlú yìí sì ni ìkòkò ìdáná ṣùgbọ́n èmi yóò le yín jáde níbẹ̀.
8 Hagi tamagra kazinkanonku korora hazankina, Nagra bainati kazinknonu hara huramantegahue huno Ra Anumzana hankavenentake Anumzamo'a hie.
Ẹ bẹ̀rù idà, èmi yóò sì mú idà wá sórí yín, bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.
9 Hagi rankumapintira tamahe kasopetre'na ru vahe zamazampi tamavrente'nugeno, ru vahe'mo'za knazana tamigahaze.
Èmi yóò lé yín jáde kúrò ní ìlú yìí, èmi yóò sì fà yín lé àjèjì lọ́wọ́, èmi yóò sì mú ìdájọ́ ṣẹ lé yín lórí.
10 Hagi bainati kazinteti tamaheme vu'na Israeli vahe mopa atupare uhanati'nugeta, Nagrikura Ra Anumza mani'ne huta keta antahita hugahaze.
Nípa idà ni ẹ̀yin yóò ṣubú, èmi yóò sì ṣe ìdájọ́ yín ní àwọn ààlà ìlú Israẹli. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
11 Hagi ama rankumamo'a tamagritera kavognara osanigeno, ete tamagra ama ana kavofi afu ame'a meaza huta knarera huta omanigahaze. Hagi tamagrira knazana tamami'na vu'na Israeli vahe mopa atupare uhanatigahue.
Ìlú yìí kò ní i jẹ́ ìkòkò ìdáná, bẹ́ẹ̀ ni ẹ̀yin náà kò sì ní jẹ́ ẹran nínú rẹ̀, Èmi yóò ṣe ìdájọ́ yín ní àwọn ààlà ìlú Israẹli.
12 Ana hanugeta Nagrikura Ra Anumza mani'ne huta keta antahita hugahaze. Na'ankure tamagra Nagri kasegea ovariri'naze. Hianagi tamagri tavaonte'ma mani kagi'naza kumatamimpi vahe'mofo zamavu'zamava avariri'naze.
Ẹ̀yin yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nítorí pé ẹ̀yin kò tẹ̀lé àṣẹ mi ẹ̀yin kò sì pa òfin mi mọ́, ṣùgbọ́n ẹ̀yin ti hùwà gẹ́gẹ́ bí àwọn aláìgbàgbọ́ orílẹ̀-èdè tó yí yín ká.”
13 Hagi ana kasnampa kema nehugeno, Benaia nemofo Pelataia'a fri'ne. Ana hige'na navugosaregati mopafi mase'na rankrafa hu'na amanage hu'noe, Ra Anumzana kagra Anumzamoke! Israeli naga'ma osi'ama mani'naza naga zamahe hana hu'za nehano?
Bí mo ṣe ń sọtẹ́lẹ̀ lọ́wọ́, Pelatiah ọmọ Benaiah kú. Mo sì dojúbolẹ̀, mo sì kígbe sókè pé, “Háà! Olúwa Olódùmarè! Ṣé ìwọ yóò ha pa ìyókù Israẹli run pátápátá ni?”
14 Hagi anante Ra Anumzamo'a amanage huno nasami'ne,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá wí pé,
15 Vahe'mofo mofavremoka, Jerusalemi kumate'ma mago'ama mani'naza vahe'mo'za hu'za, kafuhe'zane kagranema magokama kinama hutama mani'naza nagamotane maka Israeli vahe'motagu'enena hu'za, Ra Anumzamofo tava'ontetira atre'za afete umani'nazageno, ama mopa eri santihareho huno tagri ko tami'ne hu'za Jerusalemi vahe'mo'za nehaze.
“Ọmọ ènìyàn, àwọn arákùnrin rẹ, àní àwọn ará rẹ, àwọn ọkùnrin nínú ìbátan rẹ, àti gbogbo ilé Israẹli pátápátá, ni àwọn ará Jerusalẹmu ti wí fún pé, ‘Ẹ jìnnà sí Olúwa, àwa ni a fi ilẹ̀ yìí fún yín ní ìní.’
16 E'ina hu'negu amanage huo, Ra Anumzana Agra Anumzamo'a amanage hie, Zamahe kasopoge'za ru vahe mopafina mago mago hu'za umanizageno, zamahe panani huge'za ru vahe kumapina umani emani hu'nazanagi, osi'a knafima umani'naza kumatmimpina Nagra mono nozmigna hu'noe.
“Nítorí náà, sọ fún àwọn tó wà ní ìgbèkùn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, bó tilẹ̀ jẹ́ pé mo ti fọ́n wọn káàkiri orílẹ̀-èdè, síbẹ̀ fún ìgbà díẹ̀, èmi yóò jẹ́ ibi mímọ́ fún wọn níbi tí wọ́n lọ.’
17 E'ina hu'negu amanage huo huno Ra Anumzana Agra Anumzamo'a hu'ne, ru moparegama umani emanima hu'nazaregatira tamavre atru hute'na, Israeli mopa ete tamigahue.
“Nítorí náà, wí pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, Èmi yóò kó wọn jọ kúrò láàrín àwọn orílẹ̀-èdè tí mo fọ́n wọn ká sí, Èmi yóò sì fún wọn ní ilẹ̀ Israẹli padà.’
18 Hagi ete rukrahe huza mopazmire'ma esu'za Nagri navure'ma kasrino havizama hu havi anumzamofo amema'aramima me'neana emeri atre vagaregahaze.
“Wọn yóò padà síbẹ̀, wọn yóò sì mú gbogbo àwòrán ìríra rẹ̀ àti ìbọ̀rìṣà rẹ̀ kúrò.
19 Ana hanage'na Nagra magoke zamagu zamagesa nezamina, kasefa avamu zamagu'afina antegahue. Ana nehu'na hankavetino havegna hu'nea zamagu'a eri netrena, kasefa zamagu'a zamigahue.
Èmi yóò fún wọn ní ọ̀kankan; èmi yóò sì fi ẹ̀mí tuntun sínú wọn, Èmi yóò mú ọkàn òkúta kúrò lára wọn, èmi yóò sì fún wọn ní ọkàn tó rọ̀ bí ara ẹran.
20 Ana hanuge'za tra keni'ane kasegeni'anena kegava nehu'za avaririgahaze. Ana nehu'za zamagra Nagri vahe mani'nage'na, Nagra zamagri Anumza manigahue.
Kí wọn le tẹ̀lé àṣẹ mi, kí wọn sì le pa òfin mi mọ́. Wọ́n yóò jẹ́ ènìyàn mi, Èmi náà yóò sì jẹ́ Ọlọ́run wọn.
21 Hianagi havi anumzamofoma amagema nente'za kasrino havizama hu'nea zamofoma amage'ma antesia vahera zamagrama hu'naza zamavu'zmavate ante'na knazana zamitere hugahue huno Ra Anumzana Anumzamo'a hu'ne.
Ṣùgbọ́n fún àwọn tí wọ́n ń fi gbogbo ọkàn wọn sin àwọn àwòrán ìríra àti àwọn òrìṣà, Èmi yóò mú ẹ̀san ohun tí wọ́n ṣe wá sí orí wọn bẹ́ẹ̀ ni Olúwa Olódùmarè wí.”
22 Hagi anante Serabimiema nehaza ankeromo'za zamagekona rutare'za hare'za nevazageno'a wilimozanena magoka nevazageno, Israeli vahe Anumzamofo hihamu masa'amo'a zamasenirega me'nege'na ke'noe.
Àwọn kérúbù sì gbé ìyẹ́ wọn sókè pẹ̀lú kẹ̀kẹ́ lẹ́gbẹ̀ẹ́ wọn, ògo Ọlọ́run Israẹli sì wà lókè orí wọn.
23 Hagi Ra Anumzamofo masazamo'a, rankumapintira atreno marerino zage hanati kaziga me'nea agonamofona onagamu umane'ne.
Ògo Olúwa sì gòkè lọ kúrò láàrín ìlú, ó sì dúró lórí òkè tó wà ní ìlà-oòrùn ìlú náà.
24 Anama hutegeno'a ava'nagna zana negogeno Avamumo'a navresga huno Babilonima kinama hu'nazare vu'ne. Hagi anante'ma navrenoma vigeno'a ana ava'nagna zamo'a vagare'ne.
Lẹ́yìn náà, Ẹ̀mí gbé mi sókè, ó sì mú mi wá sí Kaldea lójú ìran, nípa ti Ẹ̀mí Ọlọ́run sí ọ̀dọ̀ àwọn ti ìgbèkùn. Bẹ́ẹ̀ ni ìran tí mo rí lọ kúrò ní ọ̀dọ̀ mi,
25 Ana higena Ra Anumzamo'ma naveri'ma higenama maka zama ke'noa zantamina kinafima mani'naza vahera zamasmi vagare'noe.
mo sì sọ gbogbo ohun tí Olúwa fihàn mí fún àwọn tó wà ní ìgbèkùn.

< Izikeli 11 >