< 2 Kva 1 >

1 Hanki Israeli vahe'mokizmi kini ne' Ahapu'ma fritegeno, Moapu vahe'mo'za zamagra'a zamagiare oti'naku, Israeli vahera ha'huzamante'za hu'naze.
Lẹ́yìn ikú Ahabu, Moabu ṣọ̀tẹ̀ sí Israẹli.
2 Hagi Ahasia'a Sameria kumate mani'neno mago zupa zare noma'amofo megi'a husga hunte'neno zaho'ma enerire enevuno, ananteti evuramino ra hazenke eri'ne. Anama huteno'a kato vahe'a zamasmino amanage hu'ne, Ekroni vahe'mofo anumza Balsebabunte vutma hazenkema erua hazenkefintira kanamregahufi ome antahigetma keho.
Nísinsin yìí Ahasiah ti ṣubú láàrín fèrèsé láti òkè yàrá rẹ̀ tí ó wà ní Samaria, ó sì fi ara pa. Ó sì rán oníṣẹ́, ó sì wí fún wọn pé, “Ẹ lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni, bóyá èmi ó lè rí ìwòsàn ìfarapa yìí.”
3 Hianagi Ra Anumzamofo ankeromo Tisbe kumateti kasnampa ne' Elaijana amanage huno asmi'ne, Otinka Sameria kini ne'mo'ma huzmantege'za neaza kato vahe'ma ome nezamagenunka amanage huo, Israeli kumatera Anumzana omani'negeta Ekroni vahe havi anumzana Balsebabuntegatira antahintahia ome erikura nevazo hunka zamantahigo?
Ṣùgbọ́n angẹli Olúwa wí fún Elijah ará Tiṣibi pé, “Lọ sókè kí o lọ bá ìránṣẹ́ ọba Samaria kí o sì béèrè lọ́wọ́ wọn, ‘Ṣé nítorí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli ni ẹ̀yìn fi jáde lọ ṣèwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu òrìṣà Ekroni?’
4 E'inahu avu'avazama Ahaziama hiazanku Ra Anumzamo'a huno tamagerfa huno hazenkema erino mase'nea tafetetira oraotino frigahie! Higeno Elaija'a vuno kini ne'mofo kato vahera, anankea ome zamasami'ne.
Nítorí náà ohun tí Olúwa sọ ní èyí, ‘Ìwọ kò ní kúrò lórí ibùsùn tí o dùbúlẹ̀ lé. Dájúdájú ìwọ yóò kú!’” Bẹ́ẹ̀ ni Elijah lọ.
5 Elaijama hiankema antahite'za ana kato vahe'mo'za ete'za kini nete vazageno, kini ne'mo amanage huno zamantahige'ne, na'ahigetma ame hutma aze?
Nígbà tí ìránṣẹ́ náà padà sí ọ̀dọ̀ ọba, ó béèrè ní ọwọ́ wọn pé, “Kí ni ó dé tí ẹ̀yin fi tètè padà wá?”
6 Anage hige'za agri kemofo nona'a amanage hu'za asmi'naze, Mago ne'mo kampi eme tutagiha huranteno amanage huno tasami'ne, huramantegeta e'naza kini nera amanage huta ete ome asamiho, Ra Anumzamo'a amanage huno hu'ne, Israelia Anumzana omani'negenka Ekroni vahe havi anumzana Balzebabunteti antahintahia erikura huzmantanke'zma e'nazo? E'inahu kavukvama hu'nanana, hazenkema erinka tafete'ma mase'nampintira onkanamrenka tamage hunka frigahane huno hu'ne.
Wọ́n dáhùn pé, “Ọkùnrin kan wá láti pàdé wa, ó sì wí fún wa pé, ‘Ẹ padà sí ọ̀dọ̀ ọba tí ó rán an yín kí ẹ sì wí fún un pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Ṣé nítorí wí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli ni o fi ń rán àwọn ènìyàn láti lọ ṣe ìwádìí lọ́wọ́ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni? Nítorí náà ìwọ kò ní fi orí ibùsùn tí ìwọ dùbúlẹ̀ lé sílẹ̀. Láìsí àní àní ìwọ yóò kùú!”’”
7 Anankema kini ne'mo'ma nentahino'a amanage huno zamantahige'ne, inanknahu ne'mo eme tutagihara huramanteno anankea tamasami'ne?
Ọba béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Irú ọkùnrin wo ni ó wá pàdé yín, tí ó sì sọ irú èyí fún un yín?”
8 Hige'za kini ne' Ahazia ke'mofo nona'a amanage hu'za asami'naze, Ana ne'mofo avufarera azokamoke higeno, agra zagagafamofo azokateti tro hu'naza kukena antani'neno, zagagafamofo akruteti tro hu'naza amu'nofi afafafina hu'ne. Anankema kini ne'mo'ma nentahino'a, e'i Tisbe kumateti ne' Elaija'e.
Wọ́n dáhùn pé, “Ó jẹ́ ọkùnrin tí ó wọ ẹ̀wù onírun lára pẹ̀lú ọ̀já àmùrè aláwọ tí ó gbà yíká ìbàdí rẹ̀.” Ọba sì wí pé, “Elijah ará Tiṣibi ni.”
9 Anante kini ne'mo'a 50'a sondia vahete ugote'nea ne' mago avrenteno 50'a sondia vahe'ene huzamantege'za Elaija avrenaku vu'naze. Hagi Elaija'ma mani'nea osi agonare vute'za, sondia vahete ugote'nea ne'mo'a ana agonafi marerino Elaijanku amanage hu'ne, Anumzamofo eri'za ne'moke, kini ne'mo'a kagrikura eraminka eme nago hu'ne.
Ó sì rán balógun pẹ̀lú àwọn ẹgbẹ́ ogun àádọ́ta rẹ̀. Balógun náà sì gòkè tọ Elijah lọ, ẹni tí ó jókòó ní orí òkè, wọ́n sì wí fún un pé, “Ènìyàn Ọlọ́run, ọba wí pé, ‘Sọ̀kalẹ̀ wá!’”
10 Higeno Elaija'a ana sondia vahete kva nera amanage huno asmi'ne, Nagrama Anumzamofo eri'za ne'ma mani'nesugeno'a, monafintira tevemo'a eramino kagri'ene 50'a sondia vaheka'a terasgesie. Higeno monafinti tevemo'a eramino ana sondia vahete kva ne'ene, 50'a sondia vahe'enena te fanane hu'ne.
Elijah sì dá balógun lóhùn pé, “Tí ó bá jẹ́ wí pé ènìyàn Ọlọ́run ni mí, kí iná kí ó sọ̀kalẹ̀ láti òkè ọ̀run wá kí ó sì jó ìwọ àti àwọn àádọ́ta ọkùnrin rẹ!” Nígbà náà iná náà sì sọ̀kalẹ̀ wá láti òkè ọ̀run ó sì jó balógun àti àwọn ènìyàn rẹ̀.
11 Anama higeno'a ete mago'ene kini ne' Ahazia'a sondia vahete ugagota hu'nea nera mago avrenteno 50'a sondia vahe'ene huzamantege'za Elaijana ete ome avre'za enaku vu'naze. Hagi anante uhanatite'za sondia vahete kva ne'mo'a amanage huno hu'ne, Anumzamofo eri'za ne'moka, kini ne'mo'a ame hunka eraminka eme nago huno hu'ne!
Ọba sì tún rán balógun àádọ́ta pẹ̀lú àwọn ènìyàn àádọ́ta rẹ̀ sí Elijah. Balógun náà sì wí fún un pé, “Ènìyàn Ọlọ́run, èyí ni ohun tí ọba sọ, ‘Sọ̀kalẹ̀ kánkán!’”
12 Hianagi Elaija'a kezmimofo nona'a amanage huno zamasami'ne, Nagrama Anumzamofo eri'za ne'ma tamage hu'na mani'nesugeno'a, monafinti tevemo'a eramino, kagri'ene 50'a sondia vaheka'a te vagaresie. Higeno monafinti Anumzamofo tevemo eramino ana sondia vahete kva ne'ene 50'a sondia naga'anena te fanane hu'ne.
“Tí èmi bá jẹ́ ènìyàn Ọlọ́run,” Elijah sì dáhùn, “Ǹjẹ́ kí iná kí ó sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run kí ó sì jó ọ run àti àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ!” Nígbà náà iná Ọlọ́run sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run ó sì jó o run pẹ̀lú àwọn àádọ́ta ènìyàn rẹ̀.
13 Hanki anante nampa 3rera kini ne'mo'a ru'ene sondia vahete ugagote'nea ne' mago avrenenteno, 50'a sondia vahe'ene huzamantege'za Elaijana ete ome avre'za enaku vu'naze. Hanki ana sondia vahete kva ne'mo'a Elaija'ma agonafima mani'nere vuno agiafi rena omereno amanage huno asmi'ne, Anumzamofo eri'za ne'moka muse hugantoanki, nagri'ene sondia vahe'ni'anena, antahiraminka kasunku huranto.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba tún rán balógun kẹta pẹ̀lú àwọn àádọ́ta ọkùnrin. Balógun ẹ̀ẹ̀kẹ́ta lọ sí òkè, ó sì kúnlẹ̀ lórí orókún rẹ̀ níwájú Elijah. “Ènìyàn Ọlọ́run,” Ó sì bẹ̀bẹ̀ pé, “Ìwọ ènìyàn Ọlọ́run, jọ̀wọ́ jẹ́ kí ẹ̀mí mi àti ẹ̀mí àwọn àádọ́ta ìránṣẹ́ rẹ wọ̀nyí ṣọ̀wọ́n ní ojú rẹ!
14 Hanki kote'ma monafinti tevemo'ma eramino, ugagota sondia netrene, sondia vahe zani'anema te fanenema hu'neana nagra antahi'noe. Hanki menina antahinaminka kasunku hunanto.
Wò ó, iná ti sọ̀kalẹ̀ láti ọ̀run láti jó àwọn balógun méjì àràádọ́ta àkọ́kọ́ pẹ̀lú àràádọ́ta wọn. Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ní ojúrere fún ẹ̀mí mi!”
15 Higeno anante Ra Anumzamofo ankeromo Elaijana amanage huno asmi'ne, Korora osunka agrane amne uramio. Higeno Elaija'a otino ana sondia vahete kva ne'ene uramino, kini nete vu'ne.
Angẹli Olúwa sọ fún Elijah pé, “Sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀lú rẹ̀; má ṣe bẹ̀rù rẹ̀.” Bẹ́ẹ̀ ni Elijah dìde ó sì sọ̀kalẹ̀ lọ pẹ̀lú rẹ̀ sí ọ̀dọ̀ ọba.
16 Hanki Elaija'a kini nera amanage huno asmi'ne, Ra Anumzamo'a amanage hu'ne, Israelia Anumzama mani'neana Agripintima antahi'zana eri'zankura na'ante kato vaheka'a huzmantanke'za Ekroni vahe anumzana Balsebabuntegatira antahintahia ome erikura vu'naze. E'inahu kavukvama hu'nana zantera tamagerfa hunka hazenkema erinkama tafete'ma mase'nampintira onkanamrenka frigahane.
Ó sọ fún ọba pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí, ‘Ṣé nítorí wí pé kò sí Ọlọ́run ní Israẹli fún ọ láti pè ni ìwọ fi rán ìránṣẹ́ lọ sí ọ̀dọ̀ Baali-Sebubu, òrìṣà Ekroni láti lọ ṣe ìwádìí?’ Nítorí pé o ṣe èyí, ìwọ kò ní dìde lórí ibùsùn tí o dùbúlẹ̀ lé láìsí àní àní ìwọ yóò kú!”
17 Hagi henka Ra Anumzamo'ma Elaijama asami'nea kante anteno, Ahazia'a fri'ne. Hagi Ahazia'a ne' mofavrea onte'negu huno agri negna Joramu agri nona erino kinia mani'ne. Ana knafina Jehosafati nemofo Jehoramu'ma Juda naga'mokizmi kini fore huno nampa 2 kafu mania knafi ana zana fore hu'ne.
Bẹ́ẹ̀ ó sì kú, gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ Olúwa tí Elijah ti sọ. Nítorí Ahasiah kò ní ọmọ, Jehoramu jẹ ọba ní ọdún kejì tí Jehoramu ọmọ Jehoṣafati ọba Juda.
18 Hanki Ahazia'ma kinima mani'nea knafima fore'ma nehigeno, agranema tro'ma hu'nea zantamimofo agigenkea, Israeli kini vahe'mokizmi zamagenkema krenentaza avontafepi krente'naze.
Àti ní ti gbogbo àwọn ohun tí ó ṣẹlẹ̀ nígbà ìjọba Ahasiah, àti ohun tí ó ṣe, ṣe a kò ha kọ wọ́n sí inú ìwé ọdọọdún ti àwọn ọba Israẹli?

< 2 Kva 1 >