< Jeremias 44 >
1 Daytoy ti sao nga immay kenni Jeremias maipapan kadagiti amin a taga-Juda a nagnaed iti daga ti Egipto, dagiti agnanaed idiay Migdol, Tapanes, Memfis ken iti daga ti Patros.
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ Jeremiah wá nípa àwọn Júù tí ń gbé ní ìsàlẹ̀ Ejibiti ní Migdoli, Tafanesi àti Memfisi àti ní apá òkè Ejibiti:
2 “Ni Yahweh a Mannakabalin-amin a Dios ti Israel, kastoy ti kunana: Nakitayo a mismo dagiti amin a didigra nga inyegko iti Jerusalem ken kadagiti amin a siudad ti Juda. Kitaenyo, langalang dagitoy ita. Awan ti agnanaed kadagitoy.
“Èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí: Wo ibi tí mo mú bá Jerusalẹmu àti gbogbo ìlú Juda. Lónìí, wọ́n wà ní ìyapa àti ìparun.
3 Daytoy ket gapu kadagiti dinadangkes a banbanag nga inaramidda a nakaigapoan ti panagungetko gapu iti panagpupuorda iti insenso ken panagdaydayawda kadagiti didiosen. Dagitoy ket didiosen a saanda nga am-ammo, uray dakayo, ken uray pay dagiti kapuonanyo.
Nítorí pé ibi tí wọ́n ti ṣe. Wọ́n mú mi bínú nípa tùràrí fínfín àti nípa bíbọ àwọn òrìṣà, yálà èyí tí ìwọ tàbí àwọn baba rẹ kò mọ̀.
4 Isu a namin-anok nga imbaon kadakuada dagiti amin nga adipenko a profeta. Imbaonko ida a mangibaga iti, 'Isardengyo ti panangar-aramidyo kadagitoy a makarimon a banbanag a kagurak.'
Ní ọ̀pọ̀lọpọ̀ ìgbà ní mo rán wòlíì mi, èyí tí ó wí báyìí pé, ‘Má ṣe àwọn ohun ìríra yìí tí èmi kórìíra.’
5 Ngem saanda a dimngeg. Nagkedkedda a dumngeg wenno tumalikud iti kinadangkesda nga isu iti panangpuorda kadagiti insenso kas panagdayawda kadagiti didiosen.
Ṣùgbọ́n wọn kò fetísílẹ̀ láti fi ọkàn si. Wọn kò sì yípadà kúrò nínú búburú wọn tàbí dáwọ́ ẹbọ sísun sí àwọn òrìṣà dúró.
6 Isu a ti unget ken pungtotko ket naidissuor ken nangpasged iti apoy kadagiti siudad ti Juda ken kadagiti kalsada ti Jerusalem. Isu a nagbalin dagitoy a langalang ken nadadael dagitoy, a kas iti daytoy agdama a tiempo.”
Fún ìdí èyí, ìbínú gbígbóná mi ni èmi yóò yọ sí àwọn ìlú Juda àti òpópó Jerusalẹmu àti sísọ wọ́n di ìparun bí ó ṣe wà lónìí yìí.
7 Isu nga ita, ni Yahweh a Dios a Mannakabalin-amin ken Dios ti Israel, kastoy ti kunana, “Apay ketdi nga agaramidkayo iti kinadangkes maibusor kadagiti bagbagiyo? Apay nga isinsinayo dagiti bagbagiyo manipud iti Juda—lallaki ken babbai, ubbing ken maladaga? Awanto kadakayo iti mabati.
“Báyìí tún ni Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun Israẹli wí, kí ló dé tí ẹ fi ń mu ibi ńlá yìí wá sí orí ara yín nípa yíyapa kúrò lára Juda ọkùnrin àti obìnrin, ọmọdé àti èwe, tí ẹ kò sì ku ọ̀kankan?
8 Gapu iti kinadangkesyo, pinagpungtotdak gapu kadagiti aramid dagiti imayo, iti panangpuoryo iti insenso maipaay kadagiti didiosen iti daga ti Egipto, a napanyo nagnaedan. Napankayo sadiay iti kasta ket madadaelkayo, iti kasta ket agbalinkayo a lunod ken pagang-angawan kadagiti amin a nasion iti daga.
Èéṣe tí ẹ fi mú mi bínú pẹ̀lú ohun tí ọwọ́ yín ṣe pẹ̀lú ẹbọ sísun sí àwọn òrìṣà Ejibiti, níbi tí ẹ wá láti máa gbé? Ẹ̀ ò pa ara yín run, ẹ̀ ó sì sọ ara yín di ẹni ìfiré àti ẹ̀gàn láàrín àwọn orílẹ̀-èdè ayé gbogbo.
9 Nalipatanyo kadin ti kinadangkes nga inaramid dagiti kapuonanyo, ken ti kinadangkes nga inaramid dagiti ari ti Juda ken dagiti assawada? Nalipatanyo kadin ti kinadakes nga inaramidyo ken dagiti assawayo iti daga ti Juda ken kadagiti kalsada ti Jerusalem?
Ṣé ẹ̀yin ti gbàgbé ibi tí àwọn baba ńlá yín àti àwọn ọba; àwọn ayaba Juda, àti àwọn ibi tí ẹ ti ṣe àti àwọn ìyàwó yín ní ilẹ̀ Juda àti ní òpópó Jerusalẹmu?
10 Agingga kadagitoy a tiempo, saanda pay laeng a nagpakumbaba. Saanda a bigbigbigen wenno tungtungpalen dagiti paglintegak wenno alagadek nga intedko kadakuada ken kadagiti kapuonanda.”
Láti ìgbà náà sí àkókò yìí, wọn kò rẹ ara wọn sílẹ̀ tàbí fi ìtẹríba hàn tàbí kí wọn ó tẹ̀lé òfin àti àṣẹ tí mo pa fún un yín àti àwọn baba yín.
11 Isu a ni Yahweh a Mannakabalin-amin a Dios ti Israel, kastoy ti kuna, “Dumngegkayo, ingkeddengkon nga agtignayak a maibusor kadakayo, nga iyegkon kadakayo ti didigra ken ti panangdadaelko iti entero a Juda.
“Fún ìdí èyí, báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run àwọn Israẹli wí: Mo ti pinnu láti mú ibi wá sí orí yín àti láti pa Juda run.
12 Ta alaekto dagiti nabatbati iti Juda nga agpilit a mapan agnaed idiay Egipto. Aramidek daytoy tapno mapukawdanto amin iti daga ti Egipto. Mapasagdanto babaen iti kampilan ken panagbisin. Manipud iti kababaan agingga iti kangatoan a tattao, mapukawdanto babaen iti kampilan ken panagbisin. Mataydanto ket mausarto ti nagan ti nasionda no adda agsapata, agilunod, agibabain, ken nakakaasinto ti kasasaadda.
Èmi yóò sì mú àwọn èérún tí ó kù ní Juda, tí wọ́n ṣetán láti lọ Ejibiti. Wọn yóò ṣubú pẹ̀lú idà tàbí kí wọn kú pẹ̀lú ìyàn láti orí ọmọdé títí dé àgbà ni wọn yóò kú láti ọwọ́ ìyàn tàbí idà. Wọn yóò di ẹni ìfiré àti ìparun, ẹni ẹ̀kọ̀ àti ẹni ẹ̀gàn.
13 Ta dusaekto dagiti tattao nga agnanaed iti daga ti Egipto a kas iti panangdusak iti Jerusalem babaen iti kampilan, panagbisin, ken didigra.
Èmi yóò fi ìyà jẹ ẹni tí ó bá ń gbé ní Ejibiti pẹ̀lú idà, ìyàn àti àjàkálẹ̀-ààrùn bí mo ṣe fi ìyà jẹ Jerusalẹmu.
14 Awan kadagiti nabatbati iti Juda a mapan agnaed idiay Egipto ti agsubli iti daga ti Juda, uray no kayatda ti agsubli tapno agnaedda sadiay. Awanto kadakuada ti makasubli malaksid iti sumagmamano a makalibas.”
Kò sí èyí tí ó kéré jù nínú Juda tí ó kù, tí ó ń gbé ilẹ̀ Ejibiti tí yóò sá àsálà padà sórí ilẹ̀ Juda, èyí tí wọ́n nífẹ̀ẹ́ láti padà sí, àti láti máa gbé; àyàfi àwọn aṣàtìpó mélòó kan.”
15 Kalpasanna, simmungbat kenni Jeremias dagiti amin a lallaki a makin-ammo nga agpupuor dagiti assawada iti insenso kadagiti didiosen, ken amin a babbai nga adda iti dakkel a gimong ken amin dagiti tattao nga agnanaed iti daga ti Egipto idiay Patros.
Lẹ́yìn èyí, gbogbo àwọn ọkùnrin tí ẹ bá mọ̀ pé, ìyàwó wọn sun tùràrí sí àwọn òrìṣà pẹ̀lú àwọn obìnrin tí ó bá wá àwọn ènìyàn púpọ̀, pàápàá àwọn ènìyàn tí wọ́n ń gbé ní òkè àti ìsàlẹ̀ Ejibiti, bẹ́ẹ̀ ni a wí fún Jeremiah.
16 Kinunada, “Maipanggep iti sao nga imbagam kadakami iti nagan ni Yahweh: Saankami a dumngeg kenka.
“Wọn sì wí pé, àwa kò ní fetísílẹ̀ ọ̀rọ̀ tí o bá bá wa sọ ní orúkọ Olúwa.
17 Ta pudno nga aramidenmi dagiti amin a banbanag nga imbagami nga aramidenmi: mangpuorkami iti insenso para iti Reyna ti Langit ken mangibukbokkami kadagiti daton a mainum kenkuana a kas iti inaramidmi, dagiti kapuonanmi, dagiti arimi, ken dagiti mangidadaulomi kadagiti siudad ti Juda ken kadagiti kalsada ti Jerusalem. Ket aglaplapusananto ti taraonmi, ken rumang-aykami, a saanmi a mapasaran ti aniaman a didigra.
Dájúdájú, à ó ṣe gbogbo nǹkan tí a sọ pé à ò ṣe. A ó sun tùràrí sí ayaba ọ̀run, à ó sì da ohun mímu sílẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ẹbọ sí àwa àti àwọn baba wa, àwọn ọba àti àwọn aláṣẹ ti ṣe ní àwọn ìlú Juda àti ni àwọn ìgboro Jerusalẹmu. Nígbà náà àwa ní oúnjẹ púpọ̀, a sì ṣe rere a kò sì rí ibi.
18 Idi insardengmi ti panangaramid kadagitoy a banbanag, a saankamin a nangpuor iti insenso maipaay iti Reyna ti Langit ken saankamin a nangibukbok iti daton a mainum maipaay kenkuana, nagsagabakami met amin ken adda pay natnatay kadakami babaen iti kampilan ken panagbisin.”
Ṣùgbọ́n láti ìgbà tí a ti dáwọ́ tùràrí sísun sí Ayaba Ọ̀run àti láti da ẹbọ ohun mímu fún un, àwa ti ṣaláìní ohun gbogbo, a sì run nípa idà àti nípa ìyàn.”
19 Kinuna dagiti babbai, “Idi agipupuorkami iti insenso kas daton iti Reyna ti Langit ken agibukbukbokkami iti mainum a kas daton kenkuana, inaramidmi kadi dagitoy a banbanag a saan nga ammo dagiti assawami?”
Àwọn obìnrin náà fi kún un pé, “Nígbà tí à ń jó tùràrí sí ayaba ọ̀run, tí a sì ń fi ohun mímu rú ẹbọ si; ǹjẹ́ àwọn ọkọ wa kò mọ pé àwa ń ṣe àkàrà bí i, àwòrán rẹ, àti wí pé à ń da ọtí si gẹ́gẹ́ bi ohun ìrúbọ?”
20 Ket kinuna ni Jeremias kadagiti amin a tattao—kadagiti lallaki ken babbai, ken kadagiti amin a tattao a simmungbat kenkuana—nagsao a kunana,
Wàyí o, Jeremiah sọ fún àwọn ọ̀pọ̀ ènìyàn náà, ọkùnrin àti obìnrin, tí wọn sì ń dáhùn pé,
21 “Saan kadi a malagip ni Yahweh dagiti insenso a pinuoranyo kadagiti siudad ti Juda ken kadagiti kalsada ti Jerusalem—dakayo ken dagiti kapuonanyo, dagiti ar-ariyo ken mangidadauloyo, ken dagiti tattao iti daga? Malaglagip ni Yahweh daytoy; saanna a malipatan daytoy.
“Ṣe Olúwa kò rántí ẹbọ sísun ní ìlú Juda àti àwọn ìgboro Jerusalẹmu láti ọ̀dọ̀ rẹ àti ọ̀dọ̀ àwọn baba rẹ, àwọn ọba àti àwọn aláṣẹ àti àwọn ènìyàn ìlú.
22 Ket saannan a maanusan pay daytoy gapu kadagiti dinadangkes nga ar-aramidyo, gapu kadagiti makarimon nga inaramidyo. Ket nagbalin a langalang ti dagayo, nakabutbuteng, ken lunod isu nga awanen ti agnanaed iti daytoy a kas iti agdama.
Nígbà tí Olúwa kò lè fi ara da ìwà búburú yín àti àwọn nǹkan ìríra gbogbo tí ẹ ṣe, ilẹ̀ yín sì di ohun ìfiré àti ìkọ̀sílẹ̀, láìsí olùgbé gẹ́gẹ́ bí ó ti ṣe wà lónìí.
23 Gapu ta nangpuorkayo iti insenso ket nagbasolkayo kenni Yahweh, ken gapu ta saanyo nga ipangpangag ti timekna, ti lintegna, dagiti alagadenna, wenno ti pammaneknekna iti tulagna, napasamak kadakayo daytoy a didigra a kas iti agdama.”
Nítorí pé ẹ ti sun ẹbọ, tí ẹ sì ti ṣẹ̀ sí Olúwa àti pé ẹ kò gbọ́rọ̀ sí i lẹ́nu, àti pé ẹ kò sì tẹ̀lé òfin rẹ̀ àti àwọn àṣẹ. Ibi náà yóò wá sórí rẹ àti bí o ṣe rí i.”
24 Ket kinuna ni Jeremias kadagiti amin a tattao ken kadagiti amin a babbai, “Denggenyo ti sao ni Yahweh, dakayo amin a taga-Juda nga adda iti daga ti Egipto.
Nígbà náà ni Jeremiah dáhùn pẹ̀lú obìnrin náà pé, “Gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa, ẹ̀yin ọmọ Juda tí ó wà ní Ejibiti.
25 Ni Yahweh a Mannakabalin-amin a Dios ti Isael, kastoy ti kunana, 'Agpada nga imbagayo, dakayo ken dagiti assawayo a babbai ken impatungpalyo babaen kadagiti imayo ti kinunayo a, “Pudno nga ipatungpalmi dagiti insapatami a dayawenmi ti Reyna ti Langit, a mangibukbokkami iti mainum a daton a maipaay kenkuana.” Ita, aramidenyo dagiti insapatayo; ipatungpalyo dagitoy.'
Èyí ni ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun Ọlọ́run Israẹli wí. Ìwọ àti àwọn ìyàwó rẹ fihàn pẹ̀lú àwọn ìhùwà rẹ àti àwọn ohun tí ó ṣèlérí nígbà tí o wí pé, ‘Àwa yóò mú ẹ̀jẹ́ tí a jẹ́ ṣẹ lórí sísun tùràrí àti dída ẹbọ ohun mímu sí orí ère Ayaba Ọ̀run.’ “Tẹ̀síwájú nígbà náà, ṣe ohun tí o sọ, kí o sì mú ẹ̀jẹ́ rẹ ṣẹ.
26 Isu nga ita, denggenyo ti sao ni Yahweh, dakayo amin a taga-Juda nga agnanaed iti daga ti Egipto, 'Dumngegkayo, inkarik iti natan-ok a naganko—kuna ni Yahweh. Saanton nga umawag iti naganko dagiti ngiwat ti siasinoman a tattao ti Juda iti entero a daga ti Egipto, dakayo nga agkunkuna ita, “Iti nagan ni Yahweh nga adda iti agnanayon.”
Ṣùgbọ́n gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè, gbogbo ẹ̀yin Júù tí ń gbé ilẹ̀ Ejibiti, mo gégùn ún: ‘Mo búra pẹ̀lú títóbi orúkọ mi,’ bẹ́ẹ̀ ni Olúwa wí, ‘pé kò sí ẹnikẹ́ni láti Juda tí ń gbé ibikíbi ní Ejibiti tí ó gbọdọ̀ ké pe orúkọ mi tàbí búra, “Gẹ́gẹ́ bí Ọlọ́run tí ó dá wa ti wà láààyè.”
27 Dumngegkayo, buybuyaek ida para iti pannakadidigra a saan ket a para iti pagsayaatan. Mapukawto ti tunggal tao ti Juda nga adda iti daga ti Egipto babaen iti kampilan ken panagbisin agingga a mapukawda amin.
Nítorí náà, èmi ó ṣọ wọ́n fún ibi, kì í ṣe fún rere. Àti gbogbo àwọn ọkùnrin Juda tí ó wà ní ilẹ̀ Ejibiti ni a ó parun pẹ̀lú idà àti ìyàn títí tí gbogbo wọn yóò fi tán.
28 Ket agsublinto dagiti nakalasat iti kampilan iti daga ti Juda manipud iti daga ti Egipto, bassitdanto laeng. Isu a maammoanto dagiti amin a nabatbati iti Juda a napan nagnaed iti daga ti Egipto no siasino ti akin-sao iti pumudno: ti imbagak wenno ti imbagada.
Àwọn tí ó bá sá àsálà kúrò lọ́wọ́ ìparun idà àti pípadà sí ilẹ̀ Juda láti Ejibiti yóò kéré níye. Gbogbo àwọn tí ó bá kú ní ilẹ̀ Juda, tí ó wá gbé ilẹ̀ Ejibiti yóò mọ ọ̀rọ̀ ẹni tí yóò dúró yálà tèmi tàbí tiyín.
29 Daytoyto ti pagilasinanyo—daytoy ket pakaammo ni Yahweh—a dusaenkayo iti daytoy a lugar, tapno maammoanyo a pudno a rautendakayonto dagiti sasaok babaen kadagiti didigra.'
“‘Èyí ni yóò jẹ́ àmì fún un yín pé èmi yóò fi ìyà jẹ yín níbi tí Olúwa ti sọ láti lè jẹ́ kí ẹ mọ̀ pé ìjìyà mi tí mo sọ pé ẹ̀ ó jẹ yóò ṣẹ.’
30 Kastoy ti kuna ni Yahweh, 'Dumngegkayo, dandanin ti panangiyawatko kenni Faraon Hofra nga ari ti Egipto kadagiti kabusorna ken kadagiti mangganggandat a mangkettel iti biagna. Daytoy ket kaslanto iti panangiyawatko kenni Zedekias nga ari ti Juda kenni Nebucadnesar nga ari ti Babilonia a kabusorna a nanggandat iti biagna.”'
Báyìí ni Olúwa wí: ‘Èmi yóò fi Farao Hofira ọba Ejibiti lé àwọn ọ̀tá rẹ̀ lọ́wọ́, èyí tí ó lè pa ayé rẹ́; gẹ́gẹ́ bí mo ti fi Sedekiah ọba Juda lé Nebukadnessari ọba Babeli lọ́wọ́ ọ̀tá tó ń lépa ẹ̀mí rẹ̀.’”