< Ezekiel 5 >

1 “Ket sika, anak ti tao, mangalaka iti natadem a kampilan a kas iti labaha ti barbero para iti bagim. Ipadalanmo ti labaha iti ulom ken iti barbasmo, ket mangalaka iti timbangan a pangtimbangam ken bingaybingayem ti buokmo.
“Báyìí, ọmọ ènìyàn, mú ìdá tí ó mú kí o sì fi ṣe abẹ ìfárí onígbàjámọ̀, kí o fi fá irun orí àti irùngbọ̀n rẹ. Fi irun yìí sórí ìwọ̀n kí o sì pín in.
2 Puoram ti kakatlo daytoy iti tengnga ti siudad inton malpas dagiti aldaw ti pannakalakub. Ket alaem ti maysa a kakatlo ti buok ket putdem daytoy babaen iti kampilan iti aglawlaw ti siudad. Ket iwarawaram iti angin ti maysa pay a kakatlo daytoy, ket asutekto ti kampilan a mangkamat kadagiti tattao.
Nígbà tí ọjọ́ ìgbóguntì bá parí, sun ìdákan nínú ìdámẹ́ta irun yìí níná láàrín ìlú. Mú ìdákan nínú mẹ́ta kí o fi idà bù ú káàkiri ìlú. Kí o sì tú ìdákan yòókù ká sínú afẹ́fẹ́. Nítorí pé pẹ̀lú idà ni èmi yóò máa lé wọn ká.
3 Ngem mangalaka iti sangkabassit a buok manipud kadagitoy ket igalutmo kadagiti manggas ti kawesmo.
Ṣùgbọ́n mú díẹ̀ nínú irun yìí kí o sì ta á mọ́ etí aṣọ rẹ.
4 Kalpasanna, mangalaka pay iti buok ket ipurruakmo iti tengnga ti apuy; puoram daytoy; manipud sadiay ket agkayamkamto ti apuy iti entero a balay ti Israel.”
Tún ju díẹ̀ nínú irun yìí sínú iná, kí o sun ún níná. Torí pé láti ibẹ̀ ni iná yóò ti jáde lọ sí gbogbo ilé Israẹli.
5 Kastoy ti kuna ni Yahweh nga Apo, “Daytoy ti Jerusalem, iti tengnga dagiti nasion a nangisaadak iti daytoy ken pinalawlawak daytoy kadagiti dadduma a pagilian.
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èyí ní Jerusalẹmu, tí mo gbé kalẹ̀ sí àárín àwọn Orílẹ̀-èdè, pẹ̀lú àwọn ìlú gbogbo tí o yí i ká.
6 Ngem linaksidna dagiti bilinko gapu iti kinadangkes a nalablabes pay ngem kadagiti nasion, kasta met a linaksidna dagiti paglintegak a nalablabes pay ngem kadagiti pagilian iti aglawlawna. Ket linaksidna dagiti pangngeddengko ken saanda a tinungpal dagiti paglintegak!”
Síbẹ̀ nínú ìwà búburú rẹ ó ti ṣọ̀tẹ̀ si òfin àti ìlànà mi ju àwọn orílẹ̀-èdè àti àwọn ilẹ̀ tó yí i ká lọ. Ó ti kọ òfin mi sílẹ̀, o kò sì pa ìlànà mi mọ́.
7 Kastoy ngarud ti kuna ni Yahweh nga Apo, “Gapu ta napalalo ti kinamanagbasolmo ngem kadagiti nasion iti aglawlawmo ken saanka a nagtungpal kadagiti paglintegak kasta met saanka a nagtignay segun kadagiti bilinko, ken saanka a nagtignay segun kadagiti bilin dagiti nasion iti aglawlawmo.”
“Nítorí náà, báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Nítorí pé ẹ̀yin ti ṣe àìgbọ́ràn ju àwọn orílẹ̀-èdè tó yí yín ká lọ, tí ẹ kò sì tẹ̀lé ìlànà mi tàbí kí o pa òfin mi mọ́. O kò tilẹ̀ túnṣe dáradára tó àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká.
8 Kastoy ngarud ti kuna ni Yahweh nga Apo, “Dumngegka!” Siak a mismo ti mangdusa kenka! Dusaenkanto tapno makita dagiti nasion.
“Nítorí náà báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: Èmi gan an lòdì sí ọ, Jerusalẹmu, èmi yóò sì jẹ ọ́ ní yà lójú àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká.
9 Gapu kadagiti makarimon nga aramidmo, aramidekto kenka ti saanko pay nga inaramid ken saankonto manen nga aramiden.
Nítorí gbogbo ohun ìríra rẹ, èmi yóò ṣe ohun tí n kò tí ì ṣe rí láàrín rẹ àti èyí tí n kò ní í ṣe irú rẹ̀ mọ́.
10 Ngarud kanento dagiti amma dagiti annakda iti nagtetengngaanyo ken kanen met dagiti annak a lallaki dagiti ammada, agsipud ta dusaenkayonto, ket maiwarawarakayo kadagiti amin a suli ti daga, dakayo amin a nabati!
Nítorí náà láàrín rẹ àwọn baba yóò máa jẹ ọmọ wọn, àwọn ọmọ náà yóò máa jẹ baba wọn. Èmi yóò jẹ ọ́ ní yà, èmi yóò sì tú àwọn tó bá ṣẹ́kù ká sínú ẹ̀fúùfù.
11 Kastoy ti pakaammo ni Yahweh nga Apo. Ngarud, isapatak a mapasamakto daytoy gapu ta tinulawam ti santuariok gapu kadagiti amin a didiosem a makaparurod ken dagiti makarimon nga aramidmo, ta siak a mismo ti mangkissay iti bilang dagiti tattaom; saanakto a maasian kenka, ket saankanto nga ispalen.
Nítorí náà, Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ṣe wà láààyè, nítorí pé ìwọ ti sọ ibi mímọ́ mi di àìmọ́ pẹ̀lú àwọn àwòrán ẹ̀gbin àti àwọn ohun ìríra rẹ, èmi yóò mú ojúrere mi kúrò lára rẹ, èmi kò ní í da ọ sí, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò wò ọ́ pẹ̀lú àánú mọ́.
12 Matayto ti kakatlo kadakayo babaen iti didigra, ken maibusdanto gapu iti nakaro a panagbisin. Matayto ti kakatlo kadakayo babaen iti kampilan a nangpalikawkaw kadakayo. Ket iwarawarakto ti kakatlo kadakayo kadagiti amin a suli ti daga, ken asutekto ti kampilan a mangkamat kadakuada.
Ìdámẹ́ta nínú àwọn ènìyàn rẹ yóò kú nípa àjàkálẹ̀-ààrùn tàbí kí ìyàn run wọ́n: ìdámẹ́ta yóò ṣubú nípa idà lẹ́yìn odi rẹ, èmi yóò sì tú ìdámẹ́ta yòókù ká sínú ẹ̀fúùfù, èmi yóò sì máa fi idà lé wọn.
13 Ket maan-anayton ti pungtotko, ken paginanaekton ti pungtotko kadakuada. Mapnekakto, ket maammoandanto a Siak a ni Yahweh ket nagsaoak gapu iti pungtotko idi naan-anaykon ti pungtotko kadakuada.
“Ìbínú mi yóò sì dúró, bẹ́ẹ̀ ni ìbínú gbígbóná mi yóò sì rọlẹ̀, èmi yóò sì ti gba ẹ̀san mi. Nígbà tí mo bá sì parí ìbínú mi lórí wọn, wọn ó mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀ nínú ìtara mi.
14 Pagbalinenkanto a langalang ken laisendakanto dagiti nasion iti aglawlawmo, iti imatang ti amin a lumabas.
“Èmi yóò fi ọ́ ṣòfò, èmi yóò sì sọ ọ́ di ẹ̀gàn fún àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká, àti lójú àwọn tó ń kọjá.
15 Isu nga umsien ken laisento dagiti dadduma a tattao ti Jerusalem, agbalinto a ballaag ken pagbutngan dagiti nasion iti aglawlawmo. Ipatungapalkonto ti panangukom maibusor kenka gapu iti kasta unay a pungtotko, a buyogan iti nalabes a panangtubngar—Siak a ni Yahweh, ti nangipakaammo iti daytoy!
O ó wá di ẹ̀gàn, ẹ̀sín àti ẹ̀kọ̀ àti ohun ẹ̀rù àti ìyanu fún àwọn orílẹ̀-èdè tó yí ọ ká, nígbà tí mo bá fìyà jẹ ọ́ nínú ìbínú àti nínú ìbínú gbígbóná mi. Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́ẹ̀.
16 Ipaturongkonto kenka dagiti natatadem a pana iti nakaro a panagbisin nga isunto ti pakatayam. Ta pakaroekto ti panagbisin ken tukkolekto ti sarukod ti tinapaymo.
Nígbà tí èmi ó rán ọfà búburú ìyàn sí wọn, èyí tí yóò jẹ́ fún ìparun wọn. Èmí tí èmi yóò rán run yín. Èmí yóò sì sọ ìyàn di púpọ̀ fún yín. Èmí yóò sì ṣẹ́ ọ̀pá oúnjẹ yín.
17 Iyegkonto kenka ti panagbisin ken dagiti didigra tapno saankanto nga aganak. Didigra ken pannakatay ti lumabasto kenka, ket iyegkonto ti kampilan maibusor kenka—Siak a ni Yahweh, ti nangipakaammo iti daytoy!”
Èmi yóò rán ìyàn àti ẹranko búburú sí i yín, wọn yóò fi yín sílẹ̀ ni àìlọ́mọ. Àjàkálẹ̀-ààrùn àti ìtàjẹ̀ sílẹ̀ yóò kọjá láàrín yín. Èmi yóò si mú idà wá sórí rẹ. Èmi Olúwa ló sọ bẹ́ẹ̀.”

< Ezekiel 5 >