< Ezekiel 21 >

1 Kalpasanna, immay kaniak ti sao ni Yahweh a kunana,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
2 ”Anak ti tao, sumangoka iti Jerusalem, ken agsaoka a maibusor kadagiti lugar a pagdaydayawanda; agipadtoka iti maibusor iti daga ti Israel.
“Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí ìhà Jerusalẹmu, kí o sì wàásù lòdì sí ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ilẹ̀ Israẹli.
3 Ibagam iti daga ti Israel, ‘Kastoy ti kuna ni Yahweh: Adtoy! Bumusorak kenka! Asutekto ti kampilanko manipud iti kaluban daytoy ket isinak manipud kenka ti nalinteg ken nadangkes a tao!
Kí ó sì sọ fún un pe, ‘Èyí yìí ni Olúwa wí, Èmi lòdì sí ọ. Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò sì ké olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín.
4 Iti kasta, maisinak manipud kenka ti nalinteg ken ti nadangkes a tao, rummuarto ti kampilanko manipud iti kaluban daytoy a maibusor iti amin a lasag manipud iti abagatan agingga iti amianan.
Nítorí pé, èmi yóò ké olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì sí gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí dé àríwá.
5 Ket maammoanto ti amin a lasag a Siak a ni Yahweh, ket inasutko ti kampilanko manipud iti kaluban daytoy. Ket saanton a maikaluban daytoy!’
Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; kì yóò sì padà sínú rẹ̀ mọ́.’
6 Ket sika, anak ti tao, agasugka a kasla bumtak ti barukongmo! Agasugka iti nasaem iti imatangda!
“Nítorí náà, mí ìmí ẹ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! Mí ìmí ẹ̀dùn pẹ̀lú ọkàn ìbànújẹ́ àti ẹ̀dùn ọkàn kíkorò ní iwájú wọn.
7 Kalpasanna, mapasamakto nga agsaludsodda kenka, ‘Ania aya ti makagapu nga agas-asugka? Ket kunaemto, ‘Gapu kadagiti damag nga um-umay, ta tunggal puso ket mapukawanto iti namnama, ken tunggal ima ket agleppayto! Tunggal espiritu ket agkapuyto, ken tunggal tumeng ket agkutukotto a kasla danum nga agayos. Adtoy! Um-umayen ken awan duadua a matungpalto daytoy! —kastoy ti pakaammo ni Yahweh nga Apo.”’
Bí wọ́n bá sì bi ọ́, wí pé, ‘Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń mí ìmí ẹ̀dùn?’ Ìwọ yóò wí pé, ‘Nítorí ìròyìn tí ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò sì di aláìlera; gbogbo ọkàn ní yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò sì di aláìlera bí omi?’ Ó ń bọ̀! Yóò sì wa sí ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
8 Kalpasanna, immay kaniak ti sao ni Yahweh a kunana,
Ọ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ mí wá pé:
9 “Anak ti tao, agipadtoka ken ibagam, ‘Kastoy ti kuna ti Apo: Ibagam: Maysa a kampilan! Maysa a kampilan! Mapatademto ken mapasilengto daytoy!
“Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ wí pé, èyí yìí ní Olúwa wí pé, “‘Idà kan, idà kan, tí a pọ́n, tí a sì dán pẹ̀lú,
10 Mapatademto daytoy tapno makapapatay iti adu! Mapasilengto daytoy iti kasta aggilap a kasla kimat! Rumbeng aya nga agrag-otayo iti setro ti anakko? Ti um-umay a kampilan ket kagurgurana unay ti tunggal kasta a baston!
a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀, a dán an láti máa kọ mọ̀nà! “‘Àwa o ha máa ṣe àríyá ọ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́ẹ̀.
11 Isu a maipaimanto ti kampilan tapno mapasileng, ket kalpasanna, tapno petpetan ti ima! Napatadem ti kampilan! Ket napasileng daytoy tapno maited iti ima ti maysa a mammapatay!’
“‘Idà ní a yàn láti pọ́n, kí ó lè ṣe é gbámú; a pọ́n ọn, a sì dán an, ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.
12 Agkiddawka iti tulong ken agdung-awka, anak ti tao! Ta immay dayta a kampilan kadagiti tattaok! Karaman dagiti amin a mangidadaulo ti Israel a papatayen daytoy a kampilan! Isuda dagiti tattaok, isu a danugem ti barukongmo gapu iti ladingit!
Sọkún síta, kí ó sì pohùnréré ẹ̀kún, ọmọ ènìyàn, nítorí yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi; yóò wá sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli ìbẹ̀rù ńlá yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi nítorí idà náà; nítorí náà lu oókan àyà rẹ.
13 Ta addanto ti pannubok, ngem kasano no saan nga agnanayon dayta a setro? —kastoy ti pakaammo ni Yahweh nga Apo.
“‘Ìdánwò yóò dé dandan. Tí ọ̀pá aládé Juda èyí tí idà kẹ́gàn, kò bá tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè wí.’
14 Ita, sika nga anak ti tao, agipadtoka ken agtipatka, ta rumautto ti kampilan uray iti mamintallo a daras! Maysa a kampilan para kadagiti mapapatay! Maysa a kampilan para kadagiti adu a mapapatay, a mangrangrangkay kadakuada iti sadinoman a disso!
“Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́. Jẹ́ kí idà lu ara wọn lẹ́ẹ̀méjì, kódà ní ẹ̀ẹ̀mẹta. Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, tí yóò sé wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.
15 Tapno agkebba ti pusoda ken tapno umadu dagiti pakaitibkulanda, inkabilko ti mammapatay a kampilan kadagiti ruanganda! Asida pay! Naaramid daytoy a kasla kimat, naisagana a pangpapatay!
Kí ọkàn kí ó lè yọ́ kí àwọn tí ó ṣubú le pọ̀, mo ti gbé idà sí gbogbo bodè fún ìparun. Háà! A mú kí ó kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná, a gbá a mú fún ìparun.
16 Sika a kampilan! Tumagbatka iti kannawan! Tumagbatka iti kannigid! Mapanka iti sadinoman a kayat a papanan dagiti tademmo.
Ìwọ idà, jà sí ọ̀tún kí o sì jà sí òsì lọ ibikíbi tí ẹnu rẹ bá dojúkọ.
17 Ta agtipatakto, ket kalpasanna, pabaawekto ti nakaro a pungtotko! Siak a ni Yahweh, ti nangipakaammo iti daytoy!”
Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́ ìbínú mi yóò sì rẹlẹ̀. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀.”
18 Immay manen kaniak ti sao ni Yahweh a kunana,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
19 “Ita, sika nga anak ti tao, mangaramidka iti dua a kalsada para iti umay a kampilan ti ari ti Babilonia. Ti dua a kalsada ket mangrugi iti maymaysa a daga, ken ti maysa a poste ket maysa a pagilasinan kadagiti kalsada a mangitunda a mapan iti maysa a siudad.
“Ọmọ ènìyàn la ọ̀nà méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, kí méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì sí ìkóríta ọ̀nà tí ó lọ sí ìlú náà.
20 Mangikabilka iti pagilasinan iti maysa a kalsada para iti armada ti Babilonia a mapan iti Rabba, a siudad dagiti Ammonita. Mangikabilka iti pagilasinan iti maysa pay a kalsada a mangiturong iti armada a mapan iti Juda ken iti siudad ti Jerusalem, a nasarikedkedan.
La ọ̀nà kan fún idà láti wá kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni kí òmíràn kọlu Juda, kí ó sì kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi.
21 Ta agsardengto ti ari ti Babilonia iti nagsangaan ti kalsada, tapno agbuyon iti nagsangaan ti kalsada. Gunggonennanto dagiti sumagmamano a pana ket agkiddaw iti tulong manipud kadagiti didiosenna no sadino a dalan ti turongenda. Sukimatennanto ti dalem!
Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ní ojú ọ̀nà, ní ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀wò ẹ̀dọ̀.
22 Iti makannawan nga imana ket ti sirmata a maipanggep iti Jerusalem, tapno isaganana ti troso a pangrebbada iti daytoy! Tapno iyungapna ti bibigna ket ibilinna nga irugidan ti mangpapatay! Tapno ipukkawna ti gubat! Tapno isaganana dagiti troso a pangrebbada kadagiti ruangan! Tapno mangibunton isuna kadagiti daga ken makaaramid kadagiti pagbatayanda nga umuli kadagiti pader!
Nínú ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti wá, ní ibi tí yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti mú ki wọn hó ìhó ogun láti gbé òòlù dí ẹnu-ọ̀nà ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́.
23 Arigna nga awan serserbina daytoy iti imatang dagiti adda iti Jerusalem, dagidiay a nangikari iti maysa a sapata kadagiti taga-Babilonia! Ngem pabasolento ida ti ari a linabsingda ti katulaganda tapno laeng lakubenda ida!
Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké sí àwọn tí ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò sì mú wọn lọ sí ìgbèkùn.
24 Isu a kastoy ti kuna ni Yahweh nga Apo: Gapu ta impalagipyo kaniak dagiti basbasolyo, maibutaktakto dagiti panaglabsingyo! Makitanto dagiti basolyo iti amin a tignayyo! Ta gapu iti daytoy, ipalagipyonto iti amin a masakupkayto babaen iti ima ti kabusoryo!
“Nítorí náà èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí ti ẹ̀yin ti mú ẹ̀bi yín wá sí ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ ní gbangba, ní ṣíṣe àfihàn àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun tí ó ṣe, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí, a yóò mú yín ní ìgbèkùn.
25 Ket sika, a makarimon ken nadangkes a mangiturturay iti Israel, sika a dimteng ti aldaw ti pannakadusana, sika a nagpatingga ti panangar-aramidna kadagiti nakaro a basbasol.
“‘Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti dé, ẹni tí àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti dé góńgó,
26 Kastoy ti kuna ti Apo a ni Yahweh: Ikkatem ti turbante ken ikkatem ti korona! Saanen a kas idi dagiti banbanag! Maipangato dagiti nababa ket maipababa dagiti nangato!
èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, tú ìwérí kúrò kí o sì gbé adé kúrò. Kò ní rí bí ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò sì rẹ̀ sílẹ̀.
27 Dadaelekto ti amin a banag! Maysa a nadadael! Maysa a nadadael! Mapukawto ti korona, ngem saanto a mapasamak daytoy agingga nga umay ti addaan karbengan iti daytoy. Ket itedkonto daytoy kenkuana.
Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! Kì yóò padà bọ̀ sípò bí kò ṣe pé tí ó bá wá sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.’
28 Isu a sika nga anak ti tao, agipadtoka ken ibagam, ‘Kastoy ti kuna ti Apo a ni Yahweh kadagiti tattao ti Ammon maipanggep iti umadanin a pannakaibabainda: Maysa a kampilan, naasut ti maysa a kampilan! Napatadem daytoy a pangpapatay tapno mangikisap, isu nga agbalinto daytoy a kasla kimat!
“Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn: “‘Idà kan idà kan tí á fa yọ fún ìpànìyàn tí a dán láti fi ènìyàn ṣòfò àti láti kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná!
29 Bayat a dagiti profeta ket awan masirmatada maipanggep kenka, bayat nga ar-aramidenda dagiti seremonia tapno agparnuay iti inuulbod maipanggep kenka, agdissonto daytoy a kampilan kadagiti tengnged dagiti nadangkes nga umadanin a mapapatay, dagiti tattao a dimtengen ti aldaw ti pannakadusada ken umadanin ti panagpatingga ti nakaro a panagbasbasolda.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a rí èké nípa yín àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín a yóò gbé e lé àwọn ọrùn ènìyàn búburú ti a ó pa, àwọn tí ọjọ́ wọn ti dé, àwọn tí ọjọ́ ìjìyà wọn ti dé góńgó.
30 Isublim ti kampilan iti kaluban daytoy. Iti lugar ti nakaparsuaam, iti daga a naggapuam, okumenkanto!
“‘Dá idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀. Níbi tí a gbé ṣẹ̀dá yín, ní ibi tí ẹ̀yin ti ṣẹ̀ wá.
31 Idissuorkonto ti pungtotko kenka! Rubrobak ti pungtotko a maibusor kenka ken iyawatkanto iti ima dagiti naranggas a lallaki, kadagiti lallaki a nalaing iti panagdadael!
Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín, èmi o sì fi èémí ìbínú gbígbóná mi bá yín jà.
32 Agbalinkanto a pangparubrob iti apuy! Agsayasayto ti daram iti katengngaan ti daga. Saandakanton a malagip, ta Siak a ni Yahweh, ti nangipakaammo iti daytoy!”’
Ẹ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà, a yóò ta ẹ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín, a kì yóò rántí yín mọ́; nítorí Èmi Olúwa ní ó ti wí bẹ́ẹ̀.’”

< Ezekiel 21 >