< Halelu 99 >

1 KE noho alii nei o Iehova, e haalulu mai na kanaka; ke noho nei oia iwaena o na kerubima, e naueue ka honua.
Olúwa jẹ ọba; jẹ́ kí ayé kí ó wárìrì Ó jókòó lórí ìtẹ́ kérúbù jẹ́ kí ayé kí ó wárìrì.
2 He nui o Iehova ma Ziona; Ua kiekie hoi oia maluna o na kanaka a pau.
Olúwa tóbi ní Sioni; Ó sì ga jù gbogbo orílẹ̀-èdè lọ.
3 E hiilani lakou i kou inoa nui e weliweli ai, No ka mea, ua hemolele ia.
Kí wọ́n sì yin orúkọ rẹ̀ tí ó tóbi tí ó ni ẹ̀rù, Mímọ́ ni Òun.
4 Ua makemake no hoi ka ikaika o ko alii i ka hooponopono; Ua hookumupaa oe i ka pono, Ua hana mai no oe ma ka hoopono, a ma ka pololei maloko o ka Iakoba.
Ọba náà ní agbára, ó sì fẹ́ òdodo, ìwọ fi ìdí àìṣègbè múlẹ̀; ìwọ ṣe ohun tí ó tọ́ àti ohun tí ó yẹ nínú Jakọbu.
5 E hapai oukou ia Iehova i ko kakou Akua, A e kulou hoomana ma kona keehana wawae; No ka mea, ua hoano oia.
Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa ẹ foríbalẹ̀ níbi ẹsẹ̀ rẹ̀; ó jẹ́ mímọ́.
6 O Mose, a me Aarona, iwnena o na kahuna pule, A o Samuela hoi iwaena o ka poe i hea aku i kona inoa; Kahea aku lakou ia Iehova, a ae mai oia i ka lakou.
Mose àti Aaroni wà nínú àwọn àlùfáà rẹ̀ Samuẹli wà nínú àwọn tí ó ń ké pe orúkọ rẹ̀ wọ́n ké pe Olúwa, ó sì dá wọn lóhùn.
7 Olelo mai la oia ia lakou ma ke kia ao; A malama aku la lakou i kana mau kauoha, A me ka olelopaa ana i haawi mai ai ia lakou.
Ó sọ̀rọ̀ sí wọn nínú ọ̀wọ́n àwọsánmọ̀, wọ́n pa ẹ̀rí rẹ̀ mọ́ àti ìlànà tí ó fún wọn.
8 E Iehova, ko makou Akua, pane mai no oe ia lakou; O oe no ke Akua nana i kala i ko lakou hala, Hoopai mai no nae i ka lakou mau hana.
Olúwa Ọlọ́run wa, ó dá wọn lóhùn; ó jẹ́ Ọlọ́run tí ó ń dáríjì àwọn ọmọ Israẹli ìwọ tí ó ń fi ìyà àìṣedéédéé wọn jẹ wọ́n.
9 E hapai oukou ia Iehova, i ko kakou Akua, A e hoomana aku hoi ma kona mauna hoano; No ka mea, he hoano o Iehova, ko kakou Akua.
Gbígbéga ni Olúwa Ọlọ́run wa kí a sìn ín ní òkè mímọ́ rẹ̀ nítorí Olúwa Ọlọ́run wa jẹ́ mímọ́.

< Halelu 99 >