< Halelu 89 >

1 E HOOKANI mau loa aku au i ka lokomaikai o Iehova; Ma ko'u waha e hoike aku at au i kou oiaio i kela hanauna, i keia hanauna.
Maskili ti Etani ará Esra. Èmi kọrin títóbi ìfẹ́ Olúwa títí láé; pẹ̀lú ẹnu mi ní èmi yóò jẹ́ kí a mọ òtítọ́ rẹ láti ìran dé ìran.
2 No ka mea, ua olelo no wau, e hoopaa mau loa ia kou lokomaikai; A e hookumu no hoi oe i kou oiaio ma ka lani.
Èmi ó wí pé, ìfẹ́ rẹ dúró títí láé, pé ìwọ gbe òtítọ́ rẹ kalẹ̀ ní ọ̀run fúnra rẹ̀.
3 Ua hana au i berita me kou poe i waeia, Ua hoohiki aku au no Davida, ka'u kauwa,
Ìwọ wí pé, “Èmi ti dá májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn àyànfẹ́ mi mo ti búra fún Dafidi ìránṣẹ́ mi.
4 E hoonoho paa loa wau i kau poe mamo, A e hana no hoi au i nohoalii nou no na hanauna a pau. (Sila)
‘Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ múlẹ̀ títí láé èmí ó sì máa gbe ìtẹ́ rẹ ró láti ìran dé ìran.’”
5 Na ka lani no e hoolea i kou mau mea mana, e Iehova, I kou oiaio kekahi, ma ke anaina o ka poe pono.
Àwọn ọ̀run yóò máa yin iṣẹ́ ìyanu rẹ, Olúwa, òtítọ́ rẹ ni ìpéjọpọ̀ àwọn ẹni mímọ́.
6 No ka mea, owai la ka mea ma ke aonli e ku like me Iehova? Iwaena hoi o na keiki a ka poe kiekie, e hoohalikeia me Iehova?
Ta ni ó wà ní ọ̀run tí a lè fiwé Olúwa? Ta ni nínú àwọn ọmọ alágbára ti a lè fiwé Olúwa?
7 He Akua woliweli loa hoi ia ma ke anaina o ka poe pono; A he mea ia e hopohopo ai no ka poe a pau e noho hoopuni ana ia ia.
Nínú àjọ ìgbìmọ̀ ẹni mímọ́, wọ́n bẹ̀rù Ọlọ́run gidigidi; ó sì ní ìbùyìn fún ju gbogbo àwọn tí ó yí i ká.
8 E Iehova, ke Akua o na kaua, Owai la kekahi Iehova e like me oe? Me kou oiaio hoi e hoopuni ana ia oe?
Olúwa Ọlọ́run alágbára, ta ló dàbí rẹ ìwọ jẹ́ alágbára, Olúwa, òtítọ́ rẹ sì yí ọ ká.
9 O oe no ka i hookouopono i ke kupikipikio ana o ke kai; A pii nui ae kona mau ale, nau ia e hoomalielie.
Ìwọ ń darí ríru omi Òkun; nígbà tí ó ru àwọn omi sókè, ìwọ mú wọn parọ́rọ́.
10 Ua paopao no oe ia Rahaba, me he mea la i pepehiia; I ka ikaika o kou lima, na hooauhee oe i kou poe enemi.
Ìwọ ni ó ti ya Rahabu pẹ́rẹpẹ̀rẹ bí ẹni tí a pa; ìwọ ti fi apá ọwọ́ agbára rẹ tú àwọn ọ̀tá rẹ ká.
11 Nau no ka lani, nau no hoi ka honua; Ua hookumu no oe i ke ao, a me kona mau mea e piha'i.
Tìrẹ ní àwọn ọ̀run, ayé pẹ̀lú jẹ́ tìrẹ: ayé àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀: ìwọ ti gbé wọn kalẹ̀.
12 O ke kukulu akau, a me ke kukuluhema, nau no i hana ia mau mea; E olioli no o Tabora a me Heremona i kou inoa.
Gúúsù àti àríwá ìwọ ni ó dá wọn; Tabori àti Hermoni ń fi ayọ̀ yin orúkọ rẹ.
13 He lima no kou i lako i ka ikaika: Ua ikaika no kou lima, ua kiekie hoi kou lima akau.
Ìwọ ní apá agbára; agbára ní ọwọ́ rẹ, gíga ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
14 O ka pono, a me ka hoopono, oia ke kumu o kou nohoalii: E hele ae no imua o kou maka ka lokomaikai, a me ka oiaio.
Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ: ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ àti òtítọ́ ń lọ síwájú rẹ.
15 Pomaikai ka poe kanaka ike ia leo hauoli: E Iehova, e hele no lakou ma ka malamalama o kou maka.
Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn tí wọn mọ ohùn ayọ̀ nì, Olúwa wọ́n ó máa rìn ní ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ.
16 E hauoli no lakou i kou inoa a po ka la; A ma kou pono hoi e hookiekieia'i lakou.
Wọn ń ṣògo nínú orúkọ rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́, wọn ń yin òdodo rẹ.
17 No ka mea, o oe no ka nani o ko lakou ikaika; A ma kou lokomaikai e hookiekieia'i ko makou pepeiaohao.
Nítorí ìwọ ni ògo agbára wọn; nípa ojúrere ni ìwo wá ń ṣògo.
18 No ka mea, aia no ia Iehova ko makou paku, A i ka Mea Hemolele hoi o ka Iseraela, ko makou alii.
Nítorí ti Olúwa ni asà wa, ọba wa sì ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
19 Alaila, olelo iho no oe i kou mea hemolele ma ke akaku, I mai la. Ua kau aku au i ka mana maluna o ka mea ikaika; Ua hookiekie au i ka mea i waeia mai o na kanaka.
Nígbà náà ni ìwọ sọ̀rọ̀ nínú ìran, sí àwọn olóòtítọ́ rẹ, wí pé, “Èmi ti gbé adé kalẹ̀ sórí ẹni tí ó lágbára, èmi ti gbé ẹni tí a yàn láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ga.
20 Ua loaa ia'u o Davida, o ka'u kauwa; Ua poni aku no au ia ia me kuu aila laa.
Èmi ti rí Dafidi ìránṣẹ́ mi; pẹ̀lú òróró mímọ́ mi ni mo fi yàn án.
21 E paa mau no ko'u lima me ia, A e hooikaika aku no ko'u lima ia ia.
Ìgbà gbogbo ni ọwọ́ mi yóò máa wà pẹ̀lú rẹ̀ apá mí yóò sì fi agbára fún un.
22 Aole e kii mai ka enemi i kana, Aole hoi e hookaumaha ke keiki a ka hewa ia ia.
Àwọn ọ̀tá kì yóò borí rẹ̀, àwọn ènìyàn búburú kì yóò rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
23 Na'u no e hooauhee i kona poe enemi imua ona, A e luku aku hoi i ka poe inaina mai ia ia,
Èmi yóò run àwọn ọ̀tá rẹ níwájú rẹ èmi yóò lu àwọn tí ó kórìíra rẹ bolẹ̀.
24 E noho no ko'u oiaio a me ko'u lokomaikai me ia; A ma ko'u inoa e hookiekieia'i kona pepeiaohao.
Òtítọ́ mi àti ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ yóò wà pẹ̀lú rẹ àti ní orúkọ mi ni a ó gbé ìwo rẹ ga.
25 E hookau aku au i kona lima ma ke kai, A me kona lima akau hoi ma na muliwai.
Èmi ó gbé ọwọ́ rẹ lórí òkun, àti ọwọ́ ọ̀tún rẹ lórí àwọn odo ńlá.
26 E hea mai no oia ia'u, O oe no ko'u Makua, O ko'u Akua hoi, a me ka Pohaku o ko'u hoolaia.
Òun yóò kígbe sí mi pé, ‘Ìwọ ni baba mi, Ọlọ́run mi, àti àpáta ìgbàlà mi!’
27 E hoolilo no wau ia ia i ko'u makahiapo, I mea kiekie maluna o na'lii o ka honua.
Èmi yóò ṣe é ni àkọ́bí mi, ẹni gíga ju àwọn ọba ayé.
28 E malama mau loa no wau i ko'u lokomaikai ia ia, A e ku paa loa no ko'u berita me ia.
Títí láé ni èmi yóò pa ìfẹ́ dídúró ṣinṣin mọ́ fún un, àti májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ̀ yóò dúró gbọingbọin.
29 E hoomau loa no wau i kona poe mamo, A me kona nohoalii hoi, e like me na la o ka lani.
Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ̀ múlẹ̀ títí láé, àti ìtẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ọ̀run ti wà láé.
30 Ina haalele kana poe keiki i ko'u kanawai, Aole hoi e hele ma kou hoopono ana.
“Bí àwọn ọmọ rẹ̀ bá kọ òfin mi sílẹ̀ tí wọn kò sì rìn gẹ́gẹ́ bí ìlànà mi.
31 Ina kuu aku lakou i ka'u olelo pau, Aole hoi e malama i ka'u mau kauoha;
Tí wọn bá ba ìlànà mi jẹ́ tí wọn kò sì pa àṣẹ mi mọ́,
32 Alaila e hoopai aku au i ko lakou hewa i ka laau hahau, A me ko lakou hala hoi i ke kaula.
nígbà náà ni èmi ó fì ọ̀gọ̀ bẹ ìrékọjá wọn wò; àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn pẹ̀lú pàṣán;
33 Aole nae o lawe loa aku au i ko'u lokomaikai mai ona aku. Aole hoi au e hoole i ko'u lokomaikai.
ṣùgbọ́n èmi kò ní mú ìfẹ́ mi tí ó dúró ṣinṣin kúrò lọ́dọ̀ rẹ, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò jẹ́ kí òtítọ́ mi kí ó yẹ̀.
34 Aole au e ae maluna o ka'u berita, Aole hoi e hoololi i ka olelo i puka aku ma ko'u lehelehe.
Èmi kì yóò sẹ́ májẹ̀mú mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu mi jáde padà.
35 Hookahi no ko'u hoohiki ana i ko'u hemolele, Aole au e wahahee aku ia Davida.
Lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo ni èmi ti fi ìwà mímọ́ mi búra; èmi kì yóò purọ́ fún Dafidi.
36 E mau loa ana no kana poe mamo, A me kona nohoalii, e like me ka la imua o'u.
Irú-ọmọ rẹ yóò dúró títí láé, àti ìtẹ́ rẹ̀ yóò dúró bí oòrùn níwájú mi.
37 E hoopaa mau loa ia no hoi ia, e like me ka mahina, Me he mea hoike oiaio la ma ke aouli. (Sila)
A ó fi múlẹ̀ títí láé bí òṣùpá, àti bi ẹlẹ́rìí òtítọ́ ni ọ̀run.” (Sela)
38 Aka, ua hooki mai oe, a ua hoopailua mai, A ua huhu mai no hoi oe i kau mea i poni ai.
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ti ṣá tì, ìwọ sì kórìíra; ìwọ kún fún ìrunú sí ẹni àmì òróró rẹ.
39 Ua hoole mai no hoi oe i ka berita o kau kauwa: Ua hoolei oe i kona leialii i lalo i ka lepo.
Ìwọ ti sọ májẹ̀mú ìránṣẹ́ rẹ di òfo; ìwọ tàbùkù adé rẹ nínú eruku.
40 Ua wawahi no hoi oe i kona mau pa a pau, Ua haawi mai no hoi oe i kona mau pakaua i ka lukuia.
Ìwọ ti wó gbogbo àwọn odi rẹ̀ ìwọ sọ ibi gíga rẹ̀ di ahoro.
41 Hao wale ia ia ka poe a pau e maalo ana ae malaila: He mea hoomaewaowa ia i kona poe hoalauna.
Àwọn tí ń kọjá lọ fi ṣe ìjẹ; ó ti di ẹ̀gàn àwọn olùbágbé rẹ̀.
42 Ua hookiekio oe i ka lima akau o kona poe enemi; Ua hoohauoli oe i ka poe a pau i inaina mai ia ia.
Ìwọ ti gbé ọwọ́ ọ̀tún ọ̀tá rẹ̀ sókè; ìwọ mú gbogbo ọ̀tá rẹ̀ yọ̀.
43 Ua hoohuli ae no hoi oe i ka maka o kana pahikaua, Aole hoi oe i hookupaa ia ia ma ke kaua.
Pẹ̀lú, ìwọ ti yí ojú idà rẹ̀ padà, ìwọ kò sì dúró tì í nínú ogun.
44 Ua hooki mai oe i kona nani, A ua hoolei i kona nohoalii ilalo i ka lepo.
Ìwọ ti mú ògo rẹ̀ kùnà, ìwọ si wó ìtẹ́ rẹ̀ palẹ̀ sílẹ̀ẹ́lẹ̀.
45 Ua hoopokole mai oe i na la o kona wa opiopio; Ua uhi mai no hoi oe ia ia i ka hilahila. (Sila)
Ìwọ ti gé ọjọ́ èwe rẹ̀ kúrú; ìwọ sì fi ìtìjú bò ó.
46 Pehea la ka loihi o kou hoonalo ana ia oe iho, e Iehova? E mau loa anei? E a mai nei anei kou huhu me he ahi la?
Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa? Tí ìwọ ó ha fi ara rẹ pamọ́ títí láé? Yóò ti pẹ́ to tí ìbínú rẹ yóò máa jó bí iná?
47 E hoomanao mai oe ia'u, pehea la ka loihi o ke ola ana? No ke aha la oe i hana makehewa ai i na kanaka a pau?
Rántí bí ọjọ́ mi ti kúrú tó nítorí asán ha ni ìwọ fi ṣẹ̀dá àwọn ènìyàn!
48 Owai ke kanaka e ola nei, aole oia e ike i ka make? E hoopakele anei oia i kona ola, mai ka lima aku o ka mea make? (Sila) (Sheol h7585)
Ta ni yóò wà láààyè tí kò ní rí ikú rẹ̀? Ta ló lè sá kúrò nínú agbára isà òkú? (Sheol h7585)
49 Auhea la kou lokomaikai o na manawa kahiko, e ka Haku? Ka mea au i hoohiki ai ia Davida ma ka oiaio?
Olúwa, níbo ni ìṣeun ìfẹ́ rẹ àtijọ́ wà, tí ìwọ ti fi òtítọ́ rẹ búra fún Dafidi?
50 E hoomanao mai oe, e ka Haku, i ka hoinoia o kau kauwa; Ua lawe no wau ma kou umauma i na lehulehu a pau o kou poe kanaka.
Rántí, Olúwa, bí a ti ń gan àwọn ìránṣẹ́ rẹ; bí èmi ti gbà ní àyà mi láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn,
51 No ka mea, ua hoino wale mai kou poe enemi, e Iehova, Ua hoino wale mai hoi i na kapuwai o kou mea i poniia.
ẹ̀gàn tí àwọn ọ̀tá rẹ gàn, Olúwa, tí wọn gan ipasẹ̀ ẹni àmì òróró rẹ.
52 E hoomaikaiia o Iehova, a i ka manawa pau ole. Amene, Amene.
Olùbùkún ní Olúwa títí láé.

< Halelu 89 >