< Halelu 7 >

1 E IEHOVA e ko'u Akua, ke hilinai aku nei au ia oe: E hoopakele oe ia'u i ka poe a pau nana au i hoomaau mai; E hoola mai hoi oe ia'u;
Ṣiggaioni ti Dafidi, èyí tí ó kọ sí Olúwa nípa Kuṣi, ará Benjamini. Olúwa Ọlọ́run mi, ààbò mi wà nínú rẹ; gba mí là kí o sì tú mi sílẹ̀ lọ́wọ́ àwọn tó ń lé mi,
2 O haehae mai oia i ko'u uhane me he liona la, A mokumoku au, aohe mea e ola'i.
kí wọn ó má ba à fa ọkàn mi ya gẹ́gẹ́ bí kìnnìún, wọ́n á ya á pẹ́rẹpẹ̀rẹ láìsí ẹni tí yóò gbà mí.
3 E Iehova e ko'u Akua, iua i hana au i keia; Ina he hewa iloko o ko'u mau lima;
Olúwa Ọlọ́run mi, tí èmi bá ṣe èyí tí ẹ̀bi sì wà ní ọwọ́ mi.
4 Ina i hoihoi aku au i ka hewa i ko'u hoaaloha; A i lawe wale i ka ka mea i huhu hala ole mai ia'u;
bí èmi bá ṣe ibi sí ẹni tí ń wá àlàáfíà pẹ̀lú mi, tí mo ja ọ̀tá mi lólè láìnídìí,
5 E pono e alualu mai ka enemi i ko'u uhane, a e hopu mai ia'u; A e hehi mai hoi ia i ko'u ola ilalo i ka honua, A e waiho iho hoi i ko'u uani malalo o ka lepo. (Sila)
nígbà náà, jẹ́ kí ọ̀tá mi lé mi kí wọn sì mú mi; jẹ́ kí òun kí ó tẹ ọkàn mi mọ́lẹ̀ kí wọn sì mú mi sùn nínú eruku. (Sela)
6 E ku oe iluna, e Iehova, i kou huhu, E hookiekie ae ia oe iho no ka hookano o ko'u poe enemi: E ala'e oe no'u i ka hookolokolo au i olelo mai ai.
Dìde, Olúwa, nínú ìbínú rẹ; dìde lòdì sí ìrunú àwọn ọ̀tá mi. Jí, Ọlọ́run mi; kéde òdodo.
7 Oia, e hoopuni ai ke anainakanaka ia oe: Nolaila e hoi oe i kahi kiekie no lakou.
Kí ìpéjọ àwọn ènìyàn yíká. Jọba lórí wọn láti òkè wá.
8 E hookolokolo o Iehova i na kanaka; E hoopono mai oe ia'u, e Iehova, E like me ko'u pono, a me ko'u oiaio iloko o'u.
Jẹ́ kí Olúwa ṣe ìdájọ́ àwọn ènìyàn. Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, gẹ́gẹ́ bí òdodo mi, gẹ́gẹ́ bí ìwà òtítọ́, ẹni gíga jùlọ.
9 Ke pule nei au e oki ka hana hewa o ka poe hewa; Aka, e hookupaa oe i ka poe pono; No ka mea, na ke Akua pono i hoao na naau a me na puupaa.
Ọlọ́run Olódodo, Ẹni tí ó ń wo inú àti ọkàn, tí ó ń mú òpin sí ìwà ipá ẹni búburú tí ó sì ń pa àwọn olódodo mọ́.
10 O ko'u paku, aia no i ke Akua, Nana i hoola ka poe naau kupono.
Ààbò mi ń bẹ lọ́dọ̀ Ọlọ́run, ẹni tí ń ṣe ìgbàlà òtítọ́ ní àyà.
11 Ua malama mai ke Akua i ka poe pono, Ua huhu mai ke Akua i ka hewa i na la a pau.
Ọlọ́run ni onídàájọ́ òtítọ́, Ọlọ́run tí ń sọ ìrunú rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́.
12 Ina i huli ole ia, e hookala no ia i kana pahikaua; Ua lena oia i kana kakaka, ua hooponopono no ia.
Bí kò bá yípadà, Òun yóò pọ́n idà rẹ̀ mú; ó ti fa ọrun rẹ̀ le ná, ó ti múra rẹ̀ sílẹ̀.
13 Ua hoomakaukau no hoi ia i na mea e make ai nona; Ke pana iho la oia i na pua ahi.
Ó ti pèsè ohun ìjà ikú sílẹ̀; ó ti pèsè ọfà iná sílẹ̀.
14 Aia hoi, ua nahunahu ia i ka hewa, Ua hookauhua no ia i ka ino, A ua hanau mai no hoi ia i ka wahahee.
Ẹni tí ó lóyún ohun búburú, tí ó sì lóyún wàhálà, ó bí èké jáde.
15 Ua eli iho la oia i ka lua a poopoo, Ua haule iho la no ia ilalo o ka auwaha ana i hana'i.
Ẹni tí ó gbẹ́ ọ̀fìn, tí ó kó o jáde jì sí kòtò tí ó gbẹ́ sílẹ̀.
16 E huli hou iho kana hana hewa ana maluna ona iho, A e haule iho hoi kona kolohe ana maluna o kona poo iho.
Wàhálà tí ó fà padà sórí rẹ̀; ìwà ipá rẹ̀ padà sórí ara rẹ̀.
17 E hoomaikai aku au ia Iehova no kona pono, E hoolea aku au i ka inoa o Iehova ke Kiekie loa.
Èmi ó fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí òdodo rẹ̀, èmi ó kọrin ìyìn sí Olúwa Ọ̀gá-ògo jùlọ.

< Halelu 7 >