< Halelu 46 >

1 O KE Akua ka puuhonua a me ka ikaika o kakou, He kokua kokoke loa i ka popilikia ana.
Fún adarí orin. Ti àwọn ọmọ Kora. Gẹ́gẹ́ bí ti alamoti. Orin. Ọlọ́run ni ààbò àti agbára wa ó jẹ́ olùrànlọ́wọ́ ní ìgbà ìpọ́njú.
2 Nolaila, aole makou e makau ke laweia'ku ka honua, A ke haliia'ku na mauna iwaena konu o ka moana;
Nítorí náà àwa kì yóò bẹ̀rù, bí a tilẹ̀ ṣí ayé ní ìdí, tí òkè sì ṣubú sínú Òkun.
3 Ke halulu hoi kona mau wai me ke kupikipikio, Ke haalulu hoi na mauna i kona hookiekie ana. (Sila)
Tí omi rẹ̀ tilẹ̀ ń hó tí ó sì ń mì tí àwọn òkè ńlá tilẹ̀ ń mì pẹ̀lú ọwọ́ agbára rẹ̀. (Sela)
4 He muliwai nae i hoohauoli ai kona mau waikahe i ke kulanakauhale o ke Akua, I kahi hoano o na halelewa o ka mea kiekie loa.
Odò ńlá kan wà tí ṣíṣàn rẹ̀ mú inú ìlú Ọlọ́run dùn, ibi mímọ́, níbi ti Ọ̀gá-ògo ń gbé.
5 O ke Akua ka iwaena konu ona, Aole ia e hoonauweweia: E kokua mai ke Akua ia ia i ka wehe ana'e o ke alaula.
Ọlọ́run wà pẹ̀lú rẹ̀, kò ní yẹ̀: Ọlọ́run yóò ràn án lọ́wọ́ ní kùtùkùtù òwúrọ̀.
6 Kupikipikio ae la na lahuikanaka, Nauwewe ae la na aupuni: Haawi mai la oia i kona leo, Hehee iho la ka honua.
Àwọn orílẹ̀-èdè ń bínú, àwọn ilẹ̀ ọba ṣubú, ó gbé ohun rẹ̀ sókè, ayé yọ̀.
7 O Iehova Sabaota, oia me kakou: O ko Iakoba Akua ko kakou wahi e malu ai. (Sila)
Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa, Ọlọ́run Jakọbu ni ààbò wa.
8 E hele mai e nana i na hana a Iehova, I kona hooneoneo ana ma ka honua.
Ẹ wá wo iṣẹ́ Olúwa irú ahoro tí ó ṣe ní ayé.
9 Ke hooki mai nei oia i na kaua a i ka welau o ka honua; Uhaki oia i ke kakaka, Oki pu hoi oia i ka ihe a kaawale; Hoopau hoi oia i ke kaakaua i ke ahi.
O mú ọ̀tẹ̀ tán de òpin ilẹ̀ ayé ó ṣẹ́ ọrun, ó sì gé ọ̀kọ̀ sí méjì ó fi kẹ̀kẹ́ ogun jóná.
10 E noho malie, a e ike hoi e, Owau no ke Akua. E hapaiia au iwaena o na lahuikanaka; E hookiekieia hoi au ma ka honua.
Ẹ dúró jẹ́ẹ́, kí ẹ sì mọ̀ pé èmi ní Ọlọ́run. A ó gbé mi ga nínú àwọn orílẹ̀-èdè, a ó gbé mi ga ní ayé.
11 O Iehova Sabaota oia me kakou; O ko Iakoba Akua ko kakou wahi e malu ai. (Sila)
Olúwa àwọn ọmọ-ogun wà pẹ̀lú wa; Ọlọ́run Jakọbu sì ni ààbò wa.

< Halelu 46 >