< Halelu 27 >

1 O Iehova ka ikaika o kuu ola nei; Ia wai la au e weliweli aku ai?
Ti Dafidi. Olúwa ni ìmọ́lẹ̀ mi àti ìgbàlà mi; ta ni èmi yóò bẹ̀rù? Olúwa ni ibi ìsádi ẹ̀mí mi, ẹ̀rù ta ni yóò bà mí?
2 I ka lele ana mai o ka poe hewa ia'u, O kuu mau enemi ka poe ku e mai ia'u, e ai i kuu io, Kuia iho la lakou a hina ilalo.
Nígbà tí àwọn ènìyàn búburú kọjú ìjà sí mi láti jẹ ẹran-ara mi, àní àwọn ọ̀tá mi àti àwọn abínúkú mi, wọn yóò kọsẹ̀, wọn yóò sì ṣubú.
3 Ina e hoomoana ku e mai ka poe kaua ia'u, aole e makau ko'u naau; Ina e eu ku e mai ke kaua ia'u, ma keia no wau e hilinai ai.
Bí ọmọ-ogun tilẹ̀ yí mi ká tí wọ́n sì dìde sí mi, ọkàn mi kì yóò bẹ̀rù; bí ogun tilẹ̀ dìde sí mi, nínú èyí ni ọkàn mi yóò le.
4 Hookahi no mea a'u i noi aku ai ia Iehova, oia ka'u e imi aku ai; E noho au maloko o ka hale o Iehova i na la a pau o ko'u ola ana. E nana aku i ka nani o Iehova, a e ninaninau iloko o kona luakini.
Ohun kan ni mo béèrè lọ́dọ̀ Olúwa, òhun ni èmi yóò máa wá kiri: kí èmi kí ó le wà ní ilé Olúwa ní ọjọ́ ayé mi gbogbo, kí èmi: kí ó le kíyèsi ẹwà Olúwa, kí èmi kí ó sì máa wà ní tẹmpili rẹ̀.
5 No ka mea, i ka wa popilikia e huna mai oia ia'u i kona malu: Ma kahi mehameha o kona halelewa e huna mai ai oia ia'u; E hoonoho no hoi oia ia'u maluna o ka pohaku.
Nítorí pé ní ìgbà ìpọ́njú òun yóò pa mí mọ́ nínú àgọ́ rẹ̀; níbi ìkọ̀kọ̀ àgọ́ rẹ̀ ni òun yóò pa mí mọ́; yóò sì gbé mi sókè lórí àpáta.
6 Ano e hookiekieia'e kuu poo maluna o kuu mau enemi i hoopuni mai ia'u; Nolaila e kaumaha aku ai au iloko o kona halelewa i na mohai olioli: E oli aku au, oiaio, e hoolea aku wau ia Iehova.
Ní ìsinsin yìí, a ti gbé orí mi sókè ga ju ti àwọn ọ̀tá mi lọ tí ó yí mí ká; èmi yóò rú ẹbọ nínú àgọ́ rẹ, ẹbọ ariwo àti ti ayọ̀; èmi yóò kọrin àní orin dídùn sí Olúwa.
7 E hoolohe mai, e Iehova, i kuu hea ana'ku me kuu leo; E aloha mai hoi oe ia'u, e ae mai i ka'u.
Gbọ́ ohùn mi nígbà tí ẹ̀mí bá à ń pè, Olúwa, ṣe àánú fún mi kí o sì dá mi lóhùn,
8 I kau olelo ana, E imi mai oukou i kuu alo; I aku la kuu naau ia oe, O kou alo, e Iehova, ka'u e imi ai
Ọkàn mi wí pé, “Wá ojú u rẹ̀!” Ojú rẹ, Olúwa, ni ti èmí ń wá.
9 Mai huna i kou maka ia'u; Mai hoohemo i kau kauwa nei me ka huhu. Ua kokua mai no hoi oe ia'u; Mai hookuu wale ia'u, Mai haalele hoi oe ia'u, e kuu Akua e ola'i.
Má ṣe fi ojú rẹ pamọ́ kúrò lọ́dọ̀ mi, má ṣe fi ìbínú sá ìránṣẹ́ rẹ tì; ìwọ tí o ti jẹ́ olùrànlọ́wọ́ mi, Má ṣe fi mí sílẹ̀, má sì ṣe kọ̀ mí, háà! Ọlọ́run ìgbàlà mi.
10 Aia haalele ko'u makuakane a me ko'u makuwahine ia'u, Alaila e ohi mai no hoi o Iehova ia'u.
Bí ìyá àti baba bá kọ̀ mí sílẹ̀, Olúwa yóò tẹ́wọ́ gbà mí.
11 E ao mai ia'u, e Iehova, i kou alanui; A e alakai ia'u ma ke ala maniania no kuu poe enemi.
Kọ́ mi ní ọ̀nà rẹ, Olúwa, kí o sì sìn mi lọ sí ọ̀nà tí ó tẹ́jú nítorí àwọn ọ̀tá mi.
12 Mai haawi oe ia'u i ka makemake o kuu poe enemi, No ka mea, ua ku e mai ia'u na mea hoike wahahee, A me ka poe e ha ana'e i ka huhu hewa.
Má ṣe fi mí lé ìfẹ́ àwọn ọ̀tá mi lọ́wọ́, nítorí àwọn ẹlẹ́rìí èké ti dìde sí mi, wọ́n sì mí ìmí ìkà.
13 Ina i manao ole au e ike i ka maikai o Iehova, i ka aina o ka poe ola, Ina ua maule e au.
Èmi ní ìgbàgbọ́ pé, èmi yóò rí ìre Olúwa ní ilẹ̀ alààyè.
14 E manaolana ia Iehova; i nui ka ikaika, A e hooikaika mai oia i kou naau; E hilinai aku hoi ia Iehova.
Dúró de Olúwa; kí ó jẹ alágbára, kí o sì mú ọkàn le àní dúró de Olúwa.

< Halelu 27 >