< Halelu 26 >

1 E HOOPONO mai oe ia'u, e Iehova, no ka mea, ua hele au me ko'u pono: Ua hilinai au ia Iehova, aole au e pahee.
Ti Dafidi. Ṣe ìdájọ́ mi, Olúwa, nítorí tí mo ti ń rìn nínú ìwà òtítọ́ ọ̀ mi, mo sì ti ní ìgbẹ́kẹ̀lé nínú Olúwa, ǹjẹ́ ẹsẹ̀ mi kì yóò yẹ̀.
2 E huli oe ia'u, e Iehova, a e hoike ia'u; E hoao mai oe i kuu puupaa a me kuu naau.
Wádìí mi wò, Ìwọ Olúwa, kí o sì dán mi wò, dán àyà àti ọkàn mi wò;
3 No ka mea, imua o ko'u mau maka kou lokomaikai; A ma kau olelo oiaio i hele ai au.
nítorí ìfẹ́ ẹ̀ rẹ tí ó dúró ṣinṣin ń bẹ níwájú mi, èmí sì ti rìn nínú òtítọ́ rẹ.
4 Aole au i noho pu me ka poe hookano; Aole hoi e komo pu me ka poe hookamani wale.
Èmi kò jókòó pẹ̀lú aláìṣòótọ́, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò bá àwọn àgàbàgebè wọlé.
5 Ua hoowahawaha au i ke anaina o ka poe hana ino; Aole hoi e noho pu au me ka poe hewa.
Èmi ti kórìíra àwùjọ àwọn ènìyàn búburú èmi kì yóò sì bá àwọn ènìyàn ìkà jókòó.
6 E holoi au i kuu mau lima me ka hala ole; Pela hoi au e hoopuni ai i kou kuahu, e Iehova;
Èmí ó wẹ ọwọ́ mi ní àìlẹ́ṣẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni èmi yóò sì yí pẹpẹ rẹ ká Olúwa.
7 E hoike aku au me ka leo hoomaikai, A e hai aku hoi i kau mau hana kupaianaha a pau.
Èmi yóò kọrin sókè àní orin ọpẹ́, èmi yóò sì máa sọ iṣẹ́ ìyanu rẹ̀.
8 E Iehova, ua makemake au i ka noho ana o kou hale, A me ka wahi e noho ai kou nani.
Háà Olúwa, èmí ń fẹ́ ilé rẹ níbi tí ìwọ ń gbé, àní níbi tí ògo rẹ̀ wà.
9 Mai houluulu oe i ko'u uhane me ka poe hewa; Aole hoi i kuu ola me na kanaka koko:
Má ṣe gbá mi dànù pẹ̀lú àwọn ẹlẹ́ṣẹ̀, tàbí ẹ̀mí mi pẹ̀lú àwọn ọkùnrin tí òǹgbẹ ẹ̀jẹ̀ ń gbẹ,
10 Maloko o ko lakou mau lima ke kolohe; A ua piha i na kipe ko lakou mau lima akau.
àwọn tí ọwọ́ wọn kún fún ìwà ibi, tí ọwọ́ ọ̀tún wọn kún fún àbẹ̀tẹ́lẹ̀.
11 A owau nei la, e hele au me kuu pono; E hoola mai oe ia'u, a e aloha mai ia'u.
Ṣùgbọ́n èmi ó máa rìn nínú ìwà títọ́; rà mí padà, kí o sì ṣàánú fún mi.
12 Ke ku nei kuu wawae ma kahi maniania; Maloko o na anaina e hoomaikai aku ai au ia Iehova.
Ẹsẹ̀ mi dúró lórí ilẹ̀ tí ó tẹ́jú; nínú ìjọ ńlá èmi yóò fi ìbùkún fún Olúwa.

< Halelu 26 >