< Halelu 20 >

1 E HOOLOHE mai o Iehova ia oe i ka la popilikia; I ola oe i ka inoa o ke Akua no Iakoba.
Fún adarí orin. Saamu ti Dafidi. Kí Olúwa kí ó gbóhùn rẹ ní ọjọ́ ìpọ́njú; kí orúkọ Ọlọ́run Jakọbu kí ó dáàbò bò ọ́.
2 Mai kona keenakapu mai e hoouna mai ai oia i kou mea nana e alu; Mai Ziona mai e kokua mai ai oia ia oe.
Kí ó rán ìrànlọ́wọ́ sí ọ, láti ibi mímọ́ kí ó sì tì ọ́ lẹ́yìn láti Sioni wá.
3 E hoomanao mai hoi i kau mau mohai a pau; A e hoopono mai hoi i kau mohai kuni. (Sila)
Kí ó sì rántí gbogbo ẹbọ rẹ kí ó sì gba ẹbọ sísun rẹ. (Sela)
4 E haawi mai hoi e like me kou naau iho, E hooko mai hoi i kou manao a pau.
Kí ó fi fún ọ gẹ́gẹ́ bi ti èrò ọkàn rẹ kí ó sì mú gbogbo ìmọ̀ rẹ ṣẹ.
5 I kou ola e hauoli ai makou, A i ka inoa o ko kakou Akua e kau ai kakou i ka hae: E ae mai hoi o Iehova i kau pule a pau.
Àwa yóò hó fún ayọ̀ nígbà tí o bá di aṣẹ́gun àwa yóò gbé àsíá wa sókè ní orúkọ Ọlọ́run wa. Kí Olúwa kí ó mú gbogbo ìbéèrè rẹ̀ ṣẹ.
6 Ano ua ike au, ua hoola o Iehova i kona mea i poniia; Ma kona lani hoano no ia e hoolohe mai ai ia ia, Me ka mana o kona lima akau e ola'i.
Nísinsin yìí, èmi mọ̀ wí pé, Olúwa pa ẹni àmì òróró rẹ̀ mọ́. Yóò gbọ́ láti ọ̀run mímọ́ rẹ̀ wá pẹ̀lú agbára ìgbàlà ọwọ́ ọ̀tún rẹ̀.
7 Ma na kaakaua kekahi poe, ma na lio kekahi i manao ai; Aka, e hoomanao kakou i ka inoa o Iehova o ko kakou Akua.
Àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé kẹ̀kẹ́, àwọn mìíràn gbẹ́kẹ̀ wọn lé ẹṣin, ṣùgbọ́n àwa gbẹ́kẹ̀lé orúkọ Olúwa Ọlọ́run wa.
8 Ua emi lakou, ua haule ilalo; Aka, ua ala mai nei makou a ku pono iluna.
Wọ́n wólẹ̀, ní eékún, wọ́n sì ṣubú, ṣùgbọ́n àwa dìde, a sì dúró ṣinṣin.
9 E hoola mai, e Iehova; E hoolohe mai ke alii ia makou i ko makou kahea ana.
Olúwa, fi ìṣẹ́gun fún ọba! Dá wa lóhùn nígbà tí a bá ń kígbe pè!

< Halelu 20 >