< Halelu 137 >

1 MA na muliwai o Babulona, malaila kakou i noho iho ai, A uwe aku la i ko kakou hoomanao ana ia Ziona.
Ní ẹ̀bá odò Babeli, níbẹ̀ ni àwa gbé jókòó àwa sì sọkún nígbà tí àwa rántí Sioni.
2 Ma na wilou maloko olaila, I kaulai ai makou i ko makou mea kani.
Àwa fi dùùrù wa kọ́ sí orí igi wílò, tí ó wà láàrín rẹ̀.
3 No ka mea, malaila, noi mai ka poe i lawe pio ia makou, I na olelo o ke oli; A o ka poe hoinoino ia makou, noi mai lakou e lealea makou, I mai, E oli mai oukou i ka oli o Ziona.
Nítorí pé níbẹ̀ ni àwọn tí ó kó wa ní ìgbèkùn béèrè orin lọ́wọ́ wa, àti àwọn tí ó ni wá lára béèrè ìdárayá; wọn wí pé, “Ẹ kọ orin Sioni kan fún wa!”
4 Pehea la makou e oli ai i ka oli o Iehova, Ma ka aina malihini?
Àwa ó ti ṣe kọ orin Olúwa ní ilẹ̀ àjèjì
5 Ina e hoopoina au ia oe, e Ierusalema, E poina pu no ko'u lima akua i ka hana,
Jerusalẹmu, bí èmi bá gbàgbé rẹ jẹ́ kí ọwọ́ ọ̀tún mi kí ó gbàgbé ìlò rẹ̀.
6 I ole au e hoomanao ia oe, E pipili hoi kuu aleio i ka aluna o ko'u waha; I ole hoi e kela aku ko'u makemake ia Ierusalema, Mamua o ko'u mea lealea mai.
Bí èmi kò bá rántí rẹ, jẹ́ kí ahọ́n mi kí ó lẹ̀ mọ́ èrìgì mi; bí èmi kò bá fi Jerusalẹmu ṣáájú olórí ayọ̀ mi gbogbo.
7 E Iehova, e hoomanao oe i na keiki o Edoma, I ka la o Ierusalema; I ka poe i olelo mai, E wawahi, e wawahi, A ilalo i ke kumu ona.
Olúwa rántí ọjọ́ Jerusalẹmu, lára àwọn ọmọ Edomu, àwọn ẹni tí ń wí pé, “Wó o palẹ̀, wó o palẹ̀ dé ìpìlẹ̀ rẹ̀!”
8 E ke kaikamahine o Babulona, ka mea e anaiia auanei, E pomaikai auanei ka mea hoopai aku ia oe, i ka hewa, Au i hana hewa mai ai ia makou.
Ìwọ, ọmọbìnrin Babeli, ẹni tí a ó parun; ìbùkún ni fún ẹni tí ó san án fún ọ bí ìwọ ti rò sí wa.
9 E pomaikai no hoi ka mea lalau aku i kau mau keiki, A ulupa ia lakou ilalo i na pohaku.
Ìbùkún ni fún ẹni tí ó mú ọmọ wẹ́wẹ́ rẹ tí ó sì fi wọ́n ṣán òkúta.

< Halelu 137 >