< Halelu 132 >

1 E IEHOVA, e hoomanao mai oe ia Davida, A me na pilikia ona a pau:
Orin fún ìgòkè. Olúwa, rántí Dafidi nínú gbogbo ìpọ́njú rẹ̀.
2 I ka mea ana i hoohiki ai ia Iehova, Hoohiki no oia i ka Mea ikaika o Iakoba;
Ẹni tí ó ti búra fún Olúwa, tí ó sì ṣe ìlérí fún alágbára Jakọbu pé.
3 Aole loa au e komo iloko o ka hale lewa o ko'u hale, Aole hoi au i ea maluna o ko'u wahi moe;
Nítòótọ́, èmi kì yóò wọ inú àgọ́ ilé mi lọ, bẹ́ẹ̀ èmi kì yóò gun orí àkéte mi.
4 Aole au e haawi i ka hiamoe ma ko'u mau maka, Aole hoi i ka maluhiluhi na ko'u mau lihilihi,
Èmi kì yóò fi oorun fún ojú mi, tàbí òògbé fún ìpéǹpéjú mi,
5 A loaa ia'u, he wahi no Iehova, A me kahi e noho ai no ka Mea mana o Iakoha.
títí èmi ó fi rí ibi fún Olúwa, ibùjókòó fún alágbára Jakọbu.
6 Aia hoi, ua lohe no kakou ia ma Eperata; Ua loaa ia kakou ia ma Papuululaau.
Kíyèsi i, àwa gbúròó rẹ̀ ni Efrata: àwa rí i nínú oko ẹgàn náà.
7 E komo no kakou iloko o kona mau wahi e noho ai; A e moe hoomana kakou ma kona keehana wawae.
Àwa ó lọ sínú àgọ́ rẹ̀: àwa ó máa sìn níbi àpótí ìtìsẹ̀ rẹ̀
8 E ku mai oe, e Iehova, iloko o kou wahi e maha'i; O oe, a me ka pahu o kou nani.
Olúwa, dìde sí ibi ìsinmi rẹ: ìwọ, àti àpótí agbára rẹ.
9 A kahikoia kou poe kahuna i ka pono, A e hauoli hoi kau poe haipule.
Kí a fi òdodo wọ àwọn àlùfáà rẹ: kí àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ kí ó máa hó fún ayọ̀.
10 No Davida, no kau kauwa, Mai hoohuli aku i ka maka o kou mea i poniia.
Nítorí tí Dafidi ìránṣẹ́ rẹ̀, má ṣe yí ojú ẹni òróró rẹ padà.
11 Hoohiki mai la o Iehova ia Davida ma ka oiaio, Aole loa oia i huli, mai ia mea aku, O ka hua a kou kino ka'u e hoonoho ai maluna o kou nohoalii.
Olúwa ti búra nítòótọ́ fún Dafidi, Òun kì yóò yípadà kúrò nínú rẹ̀, nínú irú-ọmọ inú rẹ ni èmi ó gbé kalẹ̀ sí orí ìtẹ́ rẹ.
12 Ina e malama kau poe keiki i ko'u berita, A me na kanawai a'u e ao aku ai ia lakou, Alaila, o ka lakou keiki o na manawa a pau, E noho no lakou ma kou noho alii.
Bí àwọn ọmọ rẹ̀ yóò bá pa májẹ̀mú mi mọ́ àti ẹ̀rí mi tí èmi yóò kọ́ wọn, àwọn ọmọ wọn pẹ̀lú yóò jókòó lórí ìtẹ́ rẹ láéláé.
13 No ka mea, ua wae mai o Iehova ia Ziona, A ua makemake oia ia, i wahi noho ai nona,
Nítorí tí Olúwa ti yan Sioni: ó ti fẹ́ ẹ fún ibùjókòó rẹ̀.
14 Eia ko'u wahi e hoomaha'i, a hiki i ka manawa pau ole; Maanei no wau e noho ai, no ka mea, Ua makemake no au ia.
Èyí ni ibi ìsinmi mi láéláé: níhìn-ín ni èmi yóò máa gbé: nítorí tí mo fẹ́ ẹ.
15 Oiaio no e hoomaikai no wau i kana ai; E hoomaona aku au i kona poe nele i ka berena.
Èmi yóò bùkún oúnjẹ rẹ̀ púpọ̀púpọ̀: èmi yóò fi oúnjẹ tẹ́ àwọn tálákà rẹ̀ lọ́rùn.
16 E kahiko no wau i kona poe kahuna i ka hoola, A e hauoli loa hoi kona poe haipule.
Èmi yóò sì fi ìgbàlà wọ àwọn àlùfáà rẹ̀: àwọn ènìyàn mímọ́ rẹ̀ yóò máa hó fún ayọ̀.
17 Malaila no wau e hookupu ai i ka pepeiaohao o Davida; Ua hoomakaukau no wau i lamaku no ko'u mea i poniia.
Níbẹ̀ ni èmi yóò gbé mú ìwo Dafidi yọ̀, èmi ti ṣe ìlànà fìtílà kan fún ẹni òróró mi.
18 E hooaahu au i kona poe enemi i ka hilahila; Maluna ona e pua ai kona leialii.
Àwọn ọ̀tá rẹ̀ ni èmi yóò fi ìtìjú wọ̀: ṣùgbọ́n lára òun tìkára rẹ̀ ni adé yóò máa gbilẹ̀.

< Halelu 132 >