< Halelu 124 >

1 I NA aole i noho pu o Iehova me kakou, Wahi a ka Iseraela,
Orin fún ìgòkè. Ti Dafidi. “Ìbá má ṣe pé Olúwa tí ó ti wà fún wa,” kí ni Israẹli kí ó máa wí nísinsin yìí;
2 Ina aole i noho pu o Iehova me kakou, I ka wa i ala ku e mai ai na kanaka ia kakou,
ìbá má ṣe pé Olúwa tó wà ní tiwa, nígbà tí àwọn ènìyàn gbógun sí wa,
3 Ina ua moni koke mai lakou ia kakou, I ka wela ana o ko lakou huhu ia kakou.
nígbà náà ni wọn ò bá gbé wà mì láààyè nígbà tí ìbínú wọn ru sí wa,
4 Ina ua poipu hoi na wai maluna o kakou, A ua hiki mai ka waikahe maluna o ko kakou uhane:
nígbà náà ni omi wọ̀n-ọn-nì ìbá bò wá mọ́lẹ̀,
5 Ina ua kahe no hoi ka waiholomoku maluna o ko kakou uhane.
nígbà náà ni agbéraga omi ìbá borí ọkàn wa.
6 E hoomaikaiia o Iehova, Ka mea haawi ole ia kakou i waiwai pio i ko lakou niho.
Olùbùkún ni Olúwa, tí kò fi wá fún wọ́n bí ohun ọdẹ fún eyín wọn.
7 Ua hoopakeleia no ko kakou uhane, Me he manu la, mai ka hei ana aku i ka poe lawaiamanu; Ua moku ka upena a ua hoopakeleia kakou.
Ọkàn wa yọ bí ẹyẹ jáde kúrò nínú okùn apẹyẹ; okùn já àwa sì yọ.
8 Aia no ko kakou kokua, maloko o ka inoa o Iehova, Ka mea nana i hana ka lani me ka honua.
Ìrànlọ́wọ́ wa ń bẹ ní orúkọ Olúwa, tí ó dá ọ̀run òun ayé.

< Halelu 124 >