< Malaki 3 >

1 A IA hoi, e hoouna auanei au i ko'u elele, Nana e hoomakaukau i ke alanui imua o'u: A e hiki wawe mai auauei ka Haku, a oukou e imi nei, iloko o kona luakini, Oia ke elele o ka berita, o ka mea a oukou e makemake nei: Ea, e hele mai ana ia, wahi a Iehova o na kaua.
“Wò ó, Èmi yóò ran ìránṣẹ́ mi, yóò tún ọ̀nà ṣe ṣáájú mi. Nígbà náà ni Olúwa, tí ẹ̀yin ń wa, yóò dé ni òjijì sí tẹmpili rẹ̀; àní oníṣẹ́ májẹ̀mú náà, tí inú yín dùn sí, yóò dé,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
2 Aka, owai ke hoomanawanui i ka la o kona hiki ana mai? Owai hoi ke ku paa i kona ikeia ana? No ka mea, e like auanei ia me ke ahi o ka mea hoohehee, A me ke sopa o ka mea hoomaemae:
Ṣùgbọ́n ta ni o lè fi ara da ọjọ́ dídé rẹ̀? Ta ni yóò sì dúró nígbà tí ó bá fi ara hàn? Nítorí òun yóò dàbí iná ẹni tí ń da fàdákà àti bi ọṣẹ alágbàfọ̀.
3 A noho ia he mea hoohehee a me ka hoomaemae i ke kala; A e huikala ia i na keiki a Levi, A e hoomaemae oia ia lakou e like me ke gula a me ke kala, I mohai aku ai lakou i ka mohai pono na Iehova.
Òun yóò sì jókòó bí ẹni tí n yọ́, tí ó sì ń da fàdákà; yóò wẹ àwọn ọmọ Lefi mọ́, yóò sì tún wọn dàbí wúrà àti fàdákà, kí wọn bá a lè mú ọrẹ òdodo wá fún Olúwa,
4 Alaila, e maliuia mai ai o Iehova i ka mohai ana a ka Iuda a me ko Ierusalema, E like me ia i na la kahiko, a i na makahiki mamua.
nígbà náà ni ọrẹ Juda àti ti Jerusalẹmu yóò jẹ́ ìtẹ́wọ́gbà fún Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ti ọjọ́ àtijọ́, àti gẹ́gẹ́ bí ọdún ìgbàanì.
5 Ke hookokoke aku nei au io oukou la e hooko i ke kanawai; E wikiwiki au i ka hoike ku e i na kahuna anaana, Me na moe kolohe, a i na mea hoohiki wahahee, Me ka poe hoonele i na mea hoolimalima i ka lakou uku, A i ka poe hoonele i ka wahinekauemake, a me ke keiki makua ole, A i ka poe hoohuli ae i ko ka malihini, aole hoi i makau ia'u, wahi a Iehova o na kaua.
“Èmi ó sì súnmọ́ yin fún ìdájọ́. Èmi yóò sì yára ṣe ẹlẹ́rìí sí àwọn oṣó, sí àwọn panṣágà, sí àwọn abúra èké, àti àwọn tí ó fi ọ̀yà alágbàṣe pọn wọn lójú, àti àwọn tí ó ni àwọn opó àti àwọn aláìní baba lára, àti sí ẹni tí kò jẹ́ kí àjèjì rí ìdájọ́ òdodo gbà, tí wọn kò sì bẹ̀rù mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
6 No ka mea, owau no Iehova, aole au e lauwili, Nolaila, aole oukou i hoopauia, e na mamo o Iakoba.
“Èmi Olúwa kò yípadà. Nítorí náà ni a kò ṣe run ẹ̀yin ọmọ Jakọbu.
7 Mai na la mai o ko oukou poe makua, Ua haalele oukou i ko'u mau kanawai, me ka malama ole. E hoi hou mai oukou ia'u nei, a e hoi hou aku au io oukou la, Wahi a Iehova o na kaua. Aka, ke ninau mai nei oukou, Ma ke aha ka makou e hoi hou aku ai?
Láti ọjọ́ àwọn baba ńlá yín wá ni ẹ̀yin tilẹ̀ ti kọ ẹ̀yìn sí ìlànà mi, tí ẹ kò sì pa wọ́n mọ́. Ẹ padà wá sí ọ̀dọ̀ mi, Èmi yóò sì padà sí ọ̀dọ̀ yín,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa yóò ṣe padà?’
8 E pono anei i ke kanaka ke hao i ka ke Akua? Aka, ua hao oukou i ka'u: a ke ninau mai nei oukou, Ma ke aha ka makou i hao ai i kau? I na hapaumi o ka waiwai, a me na mohai.
“Ènìyàn yóò ha ja Ọlọ́run ni olè bí? Síbẹ̀ ẹ̀yin ti jà mí ní olè. “Ṣùgbọ́n ẹ̀yin béèrè pé, ‘Báwo ni àwa ṣe jà ọ́ ní olè?’ “Nípa ìdámẹ́wàá àti ọrẹ.
9 Ua hoahewaia oukou i ka poino; No ka mea, ua hao oukou i ka'u, o keia lahuikanaka a pau.
Ríré ni a ó fi yín ré: gbogbo orílẹ̀-èdè yìí, nítorí ẹ̀yin ti jà mi lólè.
10 E lawe mai i na waiwai hapaumi a pau iloko o ka hale ahu waiwai, I ai maloko o ko'u hale; A e hoao mai oukou ia'u ma ia mea, wahi a Iehova o na kaua, I wehe ai paha au i na puka wai o ka Iani, A e ninini iho i ka pomaikai maluna o oukou, a lawa a hu.
Ẹ mú gbogbo ìdámẹ́wàá wá sí ilé ìṣúra, kí oúnjẹ bá à lè wà ní ilé mi, ẹ fi èyí dán mi wò,” ní Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “kí ẹ sì wò bí èmi kò bá ní sí àwọn fèrèsé ọ̀run fún yin, kí èmi sì tú ìbùkún àkúnwọ́sílẹ̀ jáde fún yín, tó bẹ́ẹ̀ tí kì yóò sì ààyè láti gbà á.
11 A no oukou wau e papa aku ai i ka mea hokai, I hoopau ole ai ia i ka hua o ko oukou aina, Aole hoi ia e hoolilo no oukou i ke kumuwaina o ke kula i mea hua ole, Wahi a Iehova o na kaua.
Èmi yóò sì bá kòkòrò ajẹnirun wí nítorí yín, òun kò sì ni run èso ilẹ̀ yín, bẹ́ẹ̀ ni àjàrà inú oko yín kò ní rẹ̀ dànù,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
12 A e kapa mai auanei na lahuikanaka a pau ia oukou, he pomaikai; No ka mea, e lilo oukou i poe mea aina i makemakeia, Wahi a Iehova o na kaua.
“Nígbà náà ni gbogbo orílẹ̀-èdè yóò sì pè yín ni alábùkún fún, nítorí tiyín yóò jẹ́ ilẹ̀ tí ó wu ni,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
13 Ua oolea ka oukou mau olelo ku e mai ia'u, wahi a Iehova; A ke ninau mai nei oukou, Heaha ka makou i olelo ku e ai ia oe?
“Ẹ̀yin ti sọ ọ̀rọ̀ líle sí mi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí. “Síbẹ̀ ẹ̀yin béèrè pé, ‘Ọ̀rọ̀ kín ni àwa sọ sí ọ?’
14 Ua olelo oukou, He mea ole ka malama i ka Akua: Heaha hoi ka pomaikai ke malama kakou i ka mea ana i kauoha mai ai, A ke hele hoi me ke kapa eleele imua o Iehova o na kaua?
“Ẹ̀yin ti wí pé, ‘Asán ni láti sin Ọlọ́run. Kí ni àwa jẹ ní èrè, nígbà tí àwa ti pa ìlànà rẹ mọ́, tí àwa sì ń rìn kiri bí ẹni tí ń ṣọ̀fọ̀ ní iwájú Olúwa àwọn ọmọ-ogun?
15 Nolaila, ke kapa nei kakou i ka poe hookiekie he pomaikai; He oiaio, ua kukuluia'e iluna ka poe hana ino; Ina hoi e hoao lakou i ke Akua, ua pakele no lakou.
Ṣùgbọ́n ní ìsinsin yìí àwa pé agbéraga ni alábùkún fún. Ní òtítọ́ ni àwọn ti ń ṣe búburú ń gbèrú sí i, kódà àwọn ti ó dán Ọlọ́run wò ni a dá sí.’”
16 Alaila, o ka poe makau ia Iehova, Kamailio pu iho lakou i kekahi i kekahi; A haliu mai la o Iehova, a hoolohe mai la, A ua kakauia ka buke hoomanao imua ona no lakou, No ka poe makau ia Iehova, a me ka poe hoomanao i koua inoa.
Nígbà náà ni àwọn tí ó bẹ̀rù Olúwa ń ba ara wọn sọ̀rọ̀, Olúwa sì tẹ́tí sí i, ó sì gbọ́. A sì kọ ìwé ìrántí kan níwájú rẹ̀, fún àwọn tí o bẹ̀rù Olúwa, tiwọn sì bọ̀wọ̀ fún orúkọ rẹ̀.
17 No'u no lakou, wahi a Iehova o na kaua, I ka la a'u e ahu iho ai i kuu waiwai; A e lokomaikai au ia lakou, E like me ka lokomaikai ana o ka makua i kana keiki nana ia I malama.
“Wọn yóò sì jẹ́ tèmi,” ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí, “ni ọjọ́ náà, tí èmi ó dá; èmi yóò sì da wọ́n sí gẹ́gẹ́ bí ènìyàn tí máa ń dá ọmọ rẹ̀ tí yóò sìn ín sí.
18 Alaila, e huli mai auanei oukou, A e nana maopopo iwaena o ka poe pono a o ka poe hewa, Iwaena hoi o ka mea malama i ke Akua, a me ka mea malama ole.
Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò rí ìyàtọ̀, ìyàtọ̀ láàrín olódodo àti ẹni búburú, láàrín ẹni tí ń sìn Ọlọ́run, àti ẹni tí kò sìn ín.

< Malaki 3 >