< Lunakanawai 17 >
1 A IA ma ka mauna o Eperaima he kanaka, o Mika kona inoa.
Nígbà náà ni ọkùnrin kan tí orúkọ rẹ̀ ń jẹ́ Mika láti agbègbè òkè Efraimu
2 I aku la ia i kona makuwahine, O kela mau apana kala, hookahi tausani, me ka haneri keu, i laweia, mai ou mai nei, ka mea au i kuamuamu ai, a i olelo mai ai hoi ma ko'u pepeiao, eia no ia'u ua kala la. Na'u no i lawe. I mai la kona makuwahine, E pomaikai ana oe ia Iehova, e kuu keiki.
sọ fún ìyá rẹ̀ pé, “Ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà èyí tí wọ́n jí mọ́ ọ lọ́wọ́, àti nípa èyí tí mo gbọ́ tí ìwọ ń ṣẹ́ èpè. Kíyèsi fàdákà náà wà ní ọ̀dọ̀ mi, èmi ni mo kó o.” Nígbà náà ni ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Kí Olúwa bùkún ọ ọmọ mi!”
3 A hoihoi aku ia i ke tausani apana kala me ka haneri keu i kona makuwahine, alaila, olelo mai la kona makuwahine, Ua hoolaa loa aku au ia kala ia Iehova, mai ko'u lima aku, i mea na ka'u keiki, e hana aku ai i kii, a i kii hooheheeia; nolaila ea, e hoihoi aku au ia ia oe.
Nígbà tí ó da ẹ̀ẹ́dẹ́gbẹ̀fà ṣékélì fàdákà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ dáhùn pé, “Èmi ti fi òtítọ́ inú ya sílífà náà sọ́tọ̀ sí Olúwa fún ọmọ mi láti fi dá ère dídá àti ère gbígbẹ́. Èmi yóò dá a padà fún ọ.”
4 Aka, hoihoi hou ae la ia i ke kala i kona makuwahine. Lawe ae la kona makuwahine i elua haneri apana kala, a haawi aku la i ka mea hoohehee kala, nana no i hana i kii, a i kii hoi i hooheheeia. Aia no laua maloko o ka hale o Mika.
Nítorí náà òun dá sílífà náà padà fún ìyá rẹ̀, ìyá rẹ̀ sì mú igba ṣékélì fàdákà, ó sì fún alágbẹ̀dẹ fàdákà ẹni tí ó fi wọ́n rọ ère fínfín àti ère dídà. Wọ́n sì kó wọn sí ilé Mika.
5 He hale akua ko ua kanaka la o ko Mika, a hana iho la ia i epoda, a i terapima, a hoolaa ae la ia i kekahi o kana mau keikikane, a lilo ia i kahuna nona.
Ọkùnrin náà, Mika sì ní ojúbọ kan. Òun sì ra ẹ̀wù efodu kan, ó sì ṣe àwọn ère kan, ó sì fi ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin ṣe àlùfáà rẹ̀.
6 Ia manawa, aole alii ma ka Iseraela. Hana no kela kanaka keia kanaka i ka mea i pono ma kona mau maka.
Ní ọjọ́ wọ̀n-ọn-nì àwọn ọmọ Israẹli kò ní ọba; olúkúlùkù ṣe bí ó ti rò pé ó tọ́ ní ojú ara rẹ́.
7 He kanaka opiopio, mailoko mai o Betelehemaiuda, no ka ohana a Iuda, he mamo na Levi, a noho no ia malaila.
Ọ̀dọ́mọkùnrin kan sì ti Bẹtilẹhẹmu ti Juda wá, tí í ṣe ìdílé Juda, ẹni tí í ṣe ẹ̀yà Lefi, òun sì ṣe àtìpó níbẹ̀,
8 Hele aku la ua kanaka la, mai ke kulanakauhale o Betelehemaiuda aku, e noho ma kahi e loaa ai, a i kona hele ana, hiki ae la ia i ka mauna o Eperaima, i ka hale o Mika.
ọkùnrin náà sì ti ìlú Bẹtilẹhẹmu ti Juda lọ, láti ṣe àtìpó ní ibikíbi tí ó bá rí. Ní ojú ọ̀nà àjò rẹ̀, ó dé ilẹ̀ Mika nínú àwọn ilẹ̀ òkè Efraimu.
9 I mai la o Mika ia ia, Mai hea mai oe i hele mai ai? I aku la ia, He Levi au, no Betelehemaiuda mai, a ke hele nei au e noho ma kahi e loaa'i.
Mika bi í pé, “Níbo ni ó ti ń bọ̀?” Ó dáhùn pé, “Ọmọ Lefi ni mí láti Bẹtilẹhẹmu Juda, mo sì ń wá ibi tí èmi yóò máa gbé.”
10 I mai la o Mika ia ia, E noho pu oe me au, i lilo oe i makua no'u, a i kahuna hoi, a e haawi aku au ia oe i umi apana kala ma ka makahiki, a i pa lole komo elua, a i ka ai no hoi; nolaila, komo aku la ua Levi nei iloko.
Mika sì sọ fún un wí pé, “Dúró lọ́dọ̀ mi kí ìwọ sì jẹ́ baba mi àti àlùfáà fún mi, èmi ó sì máa fún ọ ní ṣékélì mẹ́wàá fàdákà ní ọdọọdún, pẹ̀lú aṣọ àti oúnjẹ rẹ̀.”
11 Lealea ia Levi e noho pu me ua kanaka la, a ua like ia kanaka opiopio ia ia, me kekahi o kana mau keikikane.
Ọmọ Lefi náà sì gbà láti máa bá a gbé, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì dàbí ọ̀kan nínú àwọn ọmọ rẹ̀.
12 Hoolaa iho la o Mika i ka Levi, a lilo ua kanaka opiopio nei i kahuna nona, a noho iho la ma ka hale o Mika.
Nígbà náà ni Mika ya ará Lefi náà sí mímọ́, ọ̀dọ́mọkùnrin náà sì di àlùfáà rẹ̀, ó sì ń gbé ilé rẹ̀.
13 Alaila, i ae la o Mika, Ua ike au, e hoopomaikai ana o Iehova ia'u, no ka mea, he Levi no ko'u kahuna.
Mika sì wí pé, “Báyìí, èmi mọ̀ pé Olúwa yóò ṣe mi ní oore nítorí pé mo ní ọmọ Lefi ní àlùfáà mi.”