< Ieremia 9 >

1 A UWE! ina i lilo kuu poo i wai, a me kuu mau maka hoi i kumu waimaka, i uwe aku ai au i ke ao a me ka po, no ka poe i pephiia o ko kaikamahine o ko'u poe kanaka!
Háà! Orí ìbá jẹ́ orísun omi kí ojú mi sì jẹ́ orísun omijé! Èmi yóò sì sọkún tọ̀sán tòru nítorí ìparun àwọn ènìyàn mi.
2 Auwe hoi! ina ia'u ma ka waonahele ko ka poe hele wahi e moe ai; i haalele ai au i ko'u poe kanaka, a e hele, mai o lakou aku! no ka mea, he poe moe kolohe lakou a pau, he ahakanaka kipi.
Háà, èmi ìbá ní ni aginjù ilé àgbàwọ̀ fún àwọn arìnrìn-àjò, kí n ba à lè fi àwọn ènìyàn mi sílẹ̀ kí n sì lọ kúrò lọ́dọ̀ wọn: nítorí gbogbo wọn jẹ́ panṣágà àjọ aláìṣòótọ́ ènìyàn.
3 Lena no lakou i ko lakou mau alelo, e like me ko lakou kakaka, no ka wahahee. Aole lakou hookoa ma ka oiaio maluna o ka honua; no ka mea, hele no lakou, mai kekahi hewa, a i kekahi hewa, aole hoi lakou i ike mai ia'u, wahi a Iehova.
Wọ́n ti pèsè ahọ́n wọn sílẹ̀ bí ọfà láti fi pa irọ́; kì í ṣe nípa òtítọ́ ni wọ́n fi borí ní ilẹ̀ náà. Wọ́n ń lọ láti inú ẹ̀ṣẹ̀ kan sí òmíràn; wọn kò sì náání mi, ní Olúwa wí.
4 E makaala kela mea keia mea i kona hoalauna, mai hilinai hoi i kekahi hoahanau; no ka mea, e wahahee loa no kela hoahanau, keia hoahanau; a hele ahiahi no na hoalauna a pau.
“Ṣọ́ra fún àwọn ọ̀rẹ́ rẹ; má ṣe gbẹ́kẹ̀lé àwọn arákùnrin rẹ. Nítorí pé oníkálùkù arákùnrin jẹ́ atannijẹ, oníkálùkù ọ̀rẹ́ sì jẹ́ abanijẹ́.
5 E hoopunipuni no kela mea keia mea i kona hoalauna, aole olelo i ka mea oiaio; ua maa ko lakou alelo e olelo i na wahahee, hoomaloeloe lakou ia lakou iho e hana i ka hewa.
Ọ̀rẹ́ ń dalẹ̀ ọ̀rẹ́. Kò sì ṣí ẹni tó sọ òtítọ́, wọ́n ti kọ́ ahọ́n wọn láti máa purọ́. Wọ́n sọ ara wọn di onírẹ̀wẹ̀sì pẹ̀lú ẹ̀ṣẹ̀
6 Aia no kou wahi noho ai iwaena konu o ka hoopunipuni; no ka hoopunipuni, hoole mai lakou, aole e ike mai ia'u, wahi a Iehova.
Ó ń gbé ní àárín ẹ̀tàn; wọ́n kọ̀ láti mọ̀ mí nínú ẹ̀tàn wọn,” ni Olúwa wí.
7 Nolaila, ke olelo mai nei o Iehova o na kaua peneia. Aia hoi, e hoohehee no wau ia lakou, a e hoao hoi ia lakou; no ka mea, heaha la wau e hana'i no ke kaikamahine o ko'u poe kanaka?
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Àwọn ọmọ-ogun wí: “Wò ó, èmi dán wọn wo; nítorí pé kí ni èmi tún le è ṣe? Nítorí ẹ̀ṣẹ̀ àwọn ènìyàn mi?
8 O ko lakou alelo, he pua ia i panaia'ku, olelo no ia i ka hoopunipuni. Olelo oluolu aku kekahi i kona hoalauna me ka waha, aka, ma ka naau, ua hoohalua ia ia.
Ahọ́n wọn dàbí ọfà olóró; ó ń sọ ẹ̀tàn. Oníkálùkù sì ń fi ẹnu rẹ̀ sọ̀rọ̀ àlàáfíà sí aládùúgbò rẹ̀, ní inú ọkàn rẹ̀, ó dẹ tàkúté sílẹ̀.
9 Aole anei au e hoopai ia lakou no keia mau mea, wahi a Iehova? Aole anei e ko ka ukiuki o kuu uhane i ka lahuikanaka e like me keia?
Èmi kì yóò ha fi ìyà jẹ wọ́n nítorí èyí?” ni Olúwa wí. “Èmi kì yóò ha gbẹ̀san ara mi lórí irú orílẹ̀-èdè yìí bí?”
10 E olo no wau i ka pihe no na mauna, me ka uwe aku, a e kumakena no hoi no na wahi mauu o ka waonahele, no ka mea, ua pau lakou i ke ahi; nolaila, aole hiki kekahi ke hele malaila, aole hoi e loheia ka leo o na holoholona. Ua holo aku no ka manu o ka lewa, a me ka holoholona, ua hala lakou.
Èmi yóò sì sọkún, pohùnréré ẹkún fún àwọn òkè àti ẹkún ìrora lórí pápá oko aginjù wọ̀n-ọn-nì. Nítorí wọ́n di ahoro, wọn kò sì kọjá ní ibẹ̀. A kò sì gbọ́ igbe ẹran ọ̀sìn. Àwọn ẹyẹ ojú ọ̀run sì ti sálọ, bẹ́ẹ̀ náà ni àwọn ẹranko sì ti lọ.
11 A e hoolilo no wau ia Ierusalema i mau puu, he noho ana hoi no na ilio hihiu; a e hooneoneo no wau i na kulanakauhale o ka Iuda, aohe mea noho iloko.
“Èmi yóò sì sọ Jerusalẹmu di òkìtì àlàpà àti ihò àwọn ìkookò. Èmi ó sì sọ ìlú Juda di ahoro tí ẹnikẹ́ni kò sì ní le è gbé.”
12 Owai ke kanaka akamai i hoomaopopo i keia? A ua olelo hoi ka waha o Iehova ia ia, a nana hoi e hai aku i ka mea i make ai ka aina, a neoneo e like me ka waonahele, i ole e hele ae kekahi maloko?
Ta ni ẹni náà tí ó ní ọgbọ́n láti mòye nǹkan wọ̀nyí? Ta ni Olúwa ti sọ èyí fún, tí ó sì lè ṣàlàyé rẹ̀? Èéṣe tí ilẹ̀ náà fi ṣègbé bí aginjù, tí ẹnìkankan kò sì le là á kọjá?
13 I mai la o Iehova, No ko lakou haalele ana i ko'u kanawai, i ka mea a'u i kau ai imua o lakou, aole hoi i hoolohe i ko'u leo, aole hoi i hele mamuli o ia;
Olúwa sì wí pé, nítorí pé wọ́n ti kọ òfin mi sílẹ̀, èyí tí mo gbé kalẹ̀ níwájú wọn, wọn ṣe àìgbọ́ràn sí wọn, wọn kò sì rìn nínú òfin mi.
14 Aka, ua hele lakou mamuli o ka paakiki o ko lakou naau iho, a mamuli o na Baala hoi, na mea a ko lakou poe makua i ao mai ai ia lakou;
Dípò èyí, wọ́n ti tẹ̀lé agídí ọkàn wọn, wọ́n ti tẹ̀lé Baali gẹ́gẹ́ bí àwọn baba wọn ṣe kọ́ wọn.
15 Nolaila, penei ka olelo ana mai a Iehova o na kaua, ke Akua o ka Iseraela, Aia hoi, e hanai aku no wau ia lakou, i keia poe kanaka hoi, i ka awaawa, a e hoohainu aku au ia lakou i ka wai o ke au.
Nítorí náà, èyí ni ohun tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun, Ọlọ́run Israẹli wí, “Wò ó, Èmi yóò mú kí àwọn ènìyàn wọ̀nyí jẹ oúnjẹ kíkorò àti láti mu omi májèlé.
16 A e hoopuehu aku au ia lakou iwaena o ko na aina e, i ka poe i ike ole ia e lakou, aole hoi e ko lakou mau makuaa; e hoouna aku au i ka pahikaua mahope o lakou, a hoopau au ia lakou.
Èmi yóò sì tú wọn ká láàrín àwọn orílẹ̀-èdè, nínú èyí tí àwọn tàbí àwọn baba wọn kò mọ̀. Èmi yóò sì lépa wọn pẹ̀lú idà títí èmi yóò fi pa wọ́n run.”
17 Ke olelo mai nei o Iehova o na kaua penei, E hoonaauao oukou, a e hea aku i na wahine e olo pihe ana, i hele mai lakou, a e kii aku hoi i na wahine kumakena, i hele mai lakou;
Èyí sì ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run àwọn ọmọ-ogun wí: “Sá à wò ó nísinsin yìí! Ké sí obìnrin ti ń ṣọ̀fọ̀ nì kí ó wá; sì ránṣẹ́ pe àwọn tí ó mòye nínú wọn.
18 E hoowikiwiki hoi lakou, a e olo pihe no kakou i kahe ka wai o ko Kakou mau maka, i poha aku hoi ko kakou mau alumaka i na wai.
Jẹ́ kí wọn wá kíákíá, kí wọn wá pohùnréré ẹkún lé wa lórí títí ojú wa yóò fi sàn fún omijé tí omi yóò sì máa sàn àwọn ìpéǹpéjú wa.
19 No ka mea, ua loheia ka leo o ka uwe ana, mai Ziona mai, Nani ko kakou lukuia! Ua hilahila loa kakou, no ka mea, ua haalele kakou i ka aina, no ka mea, ua kipaku aku ko kakou wahi noho ai ia kakou.
A gbọ́ igbe ìpohùnréré ẹkún ní Sioni: ‘Àwa ti ṣègbé tó! A gbọdọ̀ fi ilẹ̀ wa sílẹ̀, nítorí pé àwọn ilé wa ti parun.’”
20 Aka, e hoolohe mai oukou i ka olelo a Iehova, o na wahine, a e lawe hoi ko oukou pepeiao i ka olelo a kona waha, a e ao aku i ka oukou mau kaikamahine i ka uwe ana, a o kela mea keia mea i kona hoalauna i ke kumakena ana.
Nísinsin yìí, ẹ̀yin obìnrin ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa; ṣí etí yín sí ọ̀rọ̀ ẹnu rẹ. Kọ́ àwọn ọmọbìnrin yín ní ìpohùnréré ẹkún, kí ẹ sì kọ́ ara yín ní arò.
21 No ka mea, ua pii mai no ka make, a iloko o ko kakou puka ma kani, ua komo no iloko o ko kakou halealii, e hooki ae ia i na kamalii mawaho, a me ua kanaka opiopio ma ke alanui.
Ikú ti gba ojú fèrèsé wa wọlé ó sì ti wọ odi alágbára wa ó ti ké àwọn ọmọ kúrò ní àdúgbò àti àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin kúrò ní gbọ̀ngàn ìta gbangba.
22 E i aku Ke olelo mai nei o Iehova penei, E haule no na kupapau o kanaka e like me ka lepo ma ke kula, e like hoi me ka pua ai mahope o ka mea hoiliili ai; aohe mea nana lakou e hoiliili.
Sọ pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “‘Òkú àwọn ènìyàn yóò ṣubú bí ààtàn ní oko gbangba àti bí ìbùkúnwọ́ lẹ́yìn olùkórè láìsí ẹnìkankan láti kó wọn jọ.’”
23 Ke i mai nei o Iehova penei, Mai kaena wale ka mea akamai i kona akamai ana, mai kaena wale hoi ka mea ikaika i kona ikaika ana, a mai kaena ka mea waiwai i kona waiwai ana;
Èyí ni ohun tí Olúwa wí: “Má ṣe jẹ́ kí ọlọ́gbọ́n yangàn nítorí agbára ọgbọ́n rẹ̀, tàbí alágbára nítorí agbára rẹ̀, tàbí ọlọ́rọ̀ nítorí ọrọ̀ rẹ̀.
24 Aka o ka mea kaena, e kaena oia i keia, i kona hoomaopopo ana, a i kona ike aua ia'u, owau no o Iehova, ka mea hana aku i ka lokomaikai, a me ka hoopono, a me ka maikai ma ka honua; no ka mea, ke lealea nei au ia mau mea, wahi a Iehova.
Ẹ jẹ́ kí ẹni tí ń ṣògo nípa èyí nì wí pé: òun ní òye, òun sì mọ̀ mí wí pé, Èmi ni Olúwa tí ń ṣe òtítọ́, ìdájọ́ àti òdodo ní ayé, nínú èyí ni mo ní inú dídùn sí,” Olúwa wí.
25 Aia hoi, e hiki mai auanei na la. wahi a Iehova, e hoopai pu aku ai au i ka poe a pau i okipoepoeia me ka poe i okipoepoe ole ia:
“Ọjọ́ ń bọ̀,” ni Olúwa wí, “tí Èmi yóò fi ìyà jẹ gbogbo àwọn tí a kọ ilà fún nínú ara nìkan.
26 I ko Aigupita, a me ka Iuda a me ka Edoma. a me na keiki a Amona, a me ka Moaba, a me na mea a pau i ako i ka uminmi, ka poe e noho la ma ka waonahelo; no ka mea, ua okipoepoe ole ia ko na aina e a pau, a ua okipoepoe ole ia ko ka hale a pau o ka Iseraela, ma ka maau.
Ejibiti, Juda, Edomu, Ammoni, Moabu àti gbogbo àwọn tí ń gbé ní ọ̀nà jíjìn réré ní aginjù. Nítorí pé gbogbo àwọn orílẹ̀-èdè wọ̀nyí jẹ́ aláìkọlà gbogbo àwọn ará ilé Israẹli sì jẹ́ aláìkọlà ọkàn.”

< Ieremia 9 >