< Isaia 27 >

1 I KELA la, me kona pahikaua kaumaha, a nui, a ikaika, E hoopai mai ai o Iehova i leviatana, i ka nahesa lele hoi, I leviatana, i nahesa kekee hoi, A e pepehi no oia i ka moo nui maloko o ke kai.
Ní ọjọ́ náà, Olúwa yóò fi idà rẹ̀ jẹ ni ní yà idà rẹ̀ a mú bí iná tí ó tóbi tí ó sì lágbára Lefitani ejò tí ń yọ̀ tẹ̀ẹ̀rẹ̀ n nì, Lefitani ejò tí ń lọ́ bìrìkìtì; Òun yóò sì pa ẹ̀mí búburú inú Òkun náà.
2 I kela la, e hookani oukou no ka pawaina.
Ní ọjọ́ náà, “Kọrin nípa ọgbà àjàrà eléso kan.
3 Owau, o Iehova, ke malama aku nei au ia, E hoomau aku au ia ia i ka wai i na manawa a pau. O hoeha mai kekahi ia ia i ka po, a i ke ao paha, E kiai aku no wau ia ia.
Èmi Olúwa ń bojútó o, Èmi ó bomirin ín láti ìgbàdégbà. Èmi ó ṣọ́ ọ tọ̀sán tòru kí ẹnikẹ́ni má ba à pa á lára.
4 Aohe huhu iloko o'u, Owai ka mea nana e hoonoho i ke kakalaioa, a me ka puakala, E ku e mai ia'u ma ke kaua ana? E hele ku e no wau ia lakou, E puhi no wau ia lakou pu.
Inú kò bí mi. Bí ẹ̀gún àti ẹ̀wọ̀n bá dojú ìjà kọ mí! Èmi yóò dìde sí wọn ní ogun, Èmi yóò sì dáná sun gbogbo wọn.
5 Ina e pili mai oia i ko'u ikaika, A hana mai ia'u ma ka mea e malu ai, E malu io no oia ia'u.
Bí bẹ́ẹ̀ kọ́, jẹ́ kí wọn wá sọ́dọ̀ mi fún ààbò; jẹ́ kí wọ́n wá àlàáfíà pẹ̀lú mi, bẹ́ẹ̀ ni, jẹ́ kí wọn wá àlàáfíà pẹ̀lú mi.”
6 E hookumu no oia i ka poe i laha mai, mai o Iakoba mai, E hoomaka no ka Iseraela, a e mohala hoi, A e hoopiha no ia i keia ao i ka hua.
Ní ọjọ́ iwájú Jakọbu yóò ta gbòǹgbò, Israẹli yóò tanná yóò sì rudi èso rẹ̀ yóò sì kún gbogbo ayé.
7 Ua hahau mai anei oia ia ia, E like me kona hahau ana mai i ka poe i hahau aku ia ia? Ua pepehiia anei oia, e like me ka pepehiia o ka poe i pepehi aku ia ia?
Ǹjẹ́ Olúwa ti lù ú gẹ́gẹ́ bí ó ti lu àwọn tí ó lù ú bolẹ̀? Ǹjẹ́ a ti pa á gẹ́gẹ́ bí a ti pa àwọn tí ó pa á?
8 I kou kipaku ana, e hahau liilii ana no oe ia ia; Ke hoopuehu nae no oia ia ia me ka makani ikaika, i ka la o ka makani mai ka hikina mai.
Nípa ogun jíjà àti ìjìyà ti o le ni ó fi dojúkọ ọ́ pẹ̀lú ìjì gbígbóná ni ó lé e jáde, gẹ́gẹ́ bí ọjọ́ tí afẹ́fẹ́ ìlà-oòrùn fẹ́.
9 Penei hoi e kalaia'i ka hewa o Iakoba, A he hua no keia a pau e kala'i i ka hala; I kona hoolilo ana i na pohaku a pau o ke kuahu, E like me na pohaku puna i ulupaia, I ala ole mai hoi na kii o Aseterota, a me na'kua kii.
Nítorí èyí báyìí ni ètùtù yóò ṣe wà fún ẹ̀ṣẹ̀ Jakọbu, èyí ni yóò sì jẹ́ èso kíkún ti ìmúkúrò ẹ̀ṣẹ̀ rẹ. Nígbà tí ó bá mú kí àwọn òkúta pẹpẹ dàbí òkúta ẹfun tí a fọ́ sí wẹ́wẹ́, kì yóò sí ère Aṣerah tàbí pẹpẹ tùràrí tí yóò wà ní ìdúró.
10 Aka, e neoneo auanei ke kulanakauhale i paa i ka pakaua, A lilo hoi i hale haaleleia, a waihoia no hoi e like me ka waonahele. Malaila no e ai ai ka bipi, Malaila no hoi ia e moe ai, A e ai no ia i kolaila muo hou.
Ìlú olódi náà ti dahoro, ibùdó ìkọ̀sílẹ̀, tí a kọ̀ tì gẹ́gẹ́ bí aginjù; níbẹ̀ ni àwọn ọmọ màlúù ti ń jẹ oko níbẹ̀ ni wọn ń sùn sílẹ̀; wọn sì jẹ gbogbo ẹ̀ka rẹ̀ tán.
11 A maloo kona mau lala, alaila, e uhaiia no lakou; E hele mai no na wahine, a e puhi ia mau mea i ke ahi. No ka mea, he lahuikanaka noonoo ole ia; Nolaila, o ka mea nana ia i hana, aole ia e aloha mai ia ia, A o ka mea nana ia i kukulu, aole ia e hana lokomaikai mai ia ia.
Nígbà tí àwọn ẹ̀ka rẹ̀ bá rọ, a ó ya wọn dànù àwọn obìnrin dé, wọ́n sì fi wọ́n dáná nítorí aláìlóye ènìyàn ni wọn jẹ́, nítorí náà ni ẹni tí ó dá wọn kì yóò ṣàánú fún wọn; bẹ́ẹ̀ ni ẹni tí ó mọ wọn kì yóò sì fi ojúrere wò wọ́n.
12 A hiki aku ia la, E uhai o Iehova, mai ka wai o kahawai mai, A hiki aku i ka muliwai o Aigupita, A e hoiliili pakahi ia oukou, E na mamo a Iseraela.
Ní ọjọ́ náà Olúwa yóò sì kó oore láti ìṣàn omi odo Eufurate wá títí dé Wadi ti Ejibiti, àti ìwọ, ìwọ ọmọ Israẹli, ni a ó kójọ ní ọ̀kọ̀ọ̀kan.
13 A hiki aku ia la, E puhiia ka pu nui, A e hele mai ka poe aneane make ma ka aina o Asuria, A o ka poe i puenuia ma ka aina o Aigupita, A e hoomana lakou ia Iehova, Ma ka mauna hoano ma Ierusalema.
Àti ní ọjọ́ náà, a ó fun fèrè ńlá kan. Gbogbo àwọn tí ń ṣègbé lọ ní Asiria àti àwọn tí ń ṣe àtìpó ní Ejibiti yóò wá sin Olúwa ní òkè mímọ́ ní Jerusalẹmu.

< Isaia 27 >