< Hosea 9 >

1 MAI hauoli, e ka Iseraela, me ka olioli, e like me na lahuikanaka; No ka mea, ua hele moe kolohe aku oe mai kou Akua aku, Ua makemake aku oe i na makana ma na kahua hehi palaoa a pau.
Má ṣe yọ̀, ìwọ Israẹli; má ṣe hó ìhó ayọ̀ bí àwọn orílẹ̀-èdè yòókù. Nítorí ẹ ti jẹ́ aláìṣòótọ́ si Ọlọ́run yín. Ẹ fẹ́ràn láti gba owó iṣẹ́ àgbèrè ní gbogbo ilẹ̀ ìpakà.
2 O ke kahua, a me kahi kaomi waina, aole e hanai laua ia lakou, A e pau auanei ka waina hou iloko ona.
Àwọn ilẹ̀ ìpakà àti ilé ìfun wáìnì kò ní fún àwọn ènìyàn lóúnjẹ wáìnì tuntun yóò tàn láìròtẹ́lẹ̀.
3 Aole lakou e noho ma ka aina o Iehova; Aka, e hoi hou o Eperaima i Aigupita; A e ai lakou i na mea haumia ma Asuria.
Wọn kò ní ṣẹ́kù sí ilé Olúwa Efraimu yóò padà sí Ejibiti, yóò sì jẹ oúnjẹ àìmọ́ ní Asiria.
4 Aole lakou e kaumaha aku i ka waina ia Iehova, Aole ia e oluolu mai ia mau mea. O ka lakou mau mohai, e like auanei ia lakou me ka berena o ka poe e kanikau ana: O ka poe a pau e ai iho ia mea e haumia lakou; No ka mea, o ka lakou berena no ko lakou ola, aole e laweia oia iloko o ka hale o Iehova.
Wọn kò ní fi ọrẹ ohun mímu fún Olúwa. Bẹ́ẹ̀ ni ìrúbọ wọn kò ní mú, inú rẹ̀ dùn. Ìrú ẹbọ bẹ́ẹ̀ yóò dàbí oúnjẹ àwọn tí ń ṣọ̀fọ̀. Gbogbo àwọn tó bá sì jẹ ẹ́ yóò di aláìmọ́. Oúnjẹ yìí yóò wà fún wọn fúnra wọn kò ní wá sí orí tẹmpili Olúwa.
5 Heaha la uanei ka oukou e hana'i i ka la ahaaina, A i ka la ahaaina a Iehova?
Kí ni ẹ̀yin ó ṣe ní ọjọ́ àjọ̀dún tí a yàn ní àwọn ọjọ́ àjọ̀dún Olúwa?
6 No ka mea, aia hoi, ua hele aku lakou mai ka luku aku: E hoakoakoa o Aigupita ia lakou, E kanu aku no o Memepi ia lakou. A o na wahi maikai i kuaiia no ko lakou kala e paapu ia i ka puakala; A maloko o ko lakou mau halelewa e kupu ka laau ooi.
Bí wọ́n tilẹ̀ yọ́ kúrò lọ́wọ́ ìparun Ejibiti yóò kó wọn jọ, Memfisi yóò sì sin wọ́n. Ibi ìsọjọ̀ fàdákà wọn ni ẹ̀gún yóò jogún, Ẹ̀gún yóò bo àpótí ìṣúra fàdákà wọn. Ẹ̀gún yóò sì bo gbogbo àgọ́ wọn.
7 Ua hiki mai na la o ka hoopai ana, Ua hiki mai na la o ka uku ana; E ike auanei ka Iseraela: Ua naaupo ke kaula, a ua hehena ke kanaka kilokilo uhane, no ka hoonuiia o kou hewa, a me ka nui o ka inaina.
Àwọn ọjọ́ ìjìyà ń bọ̀; àwọn ọjọ́ ìṣirò iṣẹ́ ti dé. Jẹ́ kí Israẹli mọ èyí. Nítorí pé ẹ̀ṣẹ̀ yín pọ̀ ìkórìíra yín sì pọ̀ gan an ni. A ka àwọn wòlíì sí òmùgọ̀, a ka ẹni ìmísí sí asínwín.
8 E kali ana o Eperaima i ke kokua, mai ko'u Akua mai: O ke kaula, he punihei ia o ka mea punihei manu ma kona aoao a pau, A he mea inaina ma ka hale o ke Akua.
Wòlíì, papọ̀ pẹ̀lú Ọlọ́run, ni olùṣọ́ ọ Efraimu. Síbẹ̀ ìdẹ̀kùn dúró dè é ní gbogbo ọ̀nà rẹ̀ àti ìkórìíra ní ilé Ọlọ́run rẹ̀.
9 Ua hana hewa nui lakou e like me na la o Gibea: Nolaila, e hoomanao mai ia i ko lakou hala, A e hoopai mai hoi i ko lakou mau hewa.
Wọ́n ti gbilẹ̀ nínú ìwà ìbàjẹ́ gẹ́gẹ́ bí i ọjọ́ Gibeah Ọlọ́run yóò rántí ìwà búburú wọn yóò sì jẹ wọ́n ní yà fún ẹ̀ṣẹ̀ wọn.
10 Ua loaa ia'u ka Iseraela e like me na hua waina ma ka waonahele; Ua ike au i ko oukou poe kupuna, e like me ka hua mua ma ka laau fiku i kona hua mua ana; Aka, hele aku la lakou ia Baala-peora, a hookaawale ia lakou iho no ka mea hilahila: A o na mea hoowahawahaia, ua like me ko lakou makemake.
“Mo rí Israẹli bí èso àjàrà ní aginjù. Mo rí àwọn baba yín, bí àkọ́pọ́n nínú igi ọ̀pọ̀tọ́ ní àkọ́so rẹ̀. Ṣùgbọ́n wọ́n tọ Baali-Peori lọ, wọ́n yà wọn sọ́tọ̀ fún òrìṣà tó ń mú ìtìjú bá ni, ohun ìríra wọn sì rí gẹ́gẹ́ bí wọn ti fẹ́.
11 A no ka Eperaima, e lele aku auanei ko lakou nani me he manu la, mai ka hanau ana mai, mai ka opu mai, a mai ka hapai ana mai.
Ògo Efraimu yóò fò lọ bí ẹyẹ kò ní sí ìfẹ́rakù, ìlóyún àti ìbímọ.
12 Ina paha e hanai lakou i na keiki a lakou, E hoonele aku au ia lakou mawaena aku o kanaka: A he poino ko lakou i ka wa a'u e haalele ai ia lakou!
Bí wọ́n tilẹ̀ tọ́ ọmọ dàgbà. Èmi yóò mú wọn ṣọ̀fọ̀ lórí gbogbo wọn. Ègbé ni fún wọn, nígbà tí mo yípadà kúrò lọ́dọ̀ wọn!
13 O Eperaima, e like me ko'u ike ana ma Turo, ua kanuia oia ma kahi maikai: Aka, e alakai aku o Eperaima i kaua poe keiki no ka mea pepehi.
Mo rí Efraimu bí ìlú Tire tí a tẹ̀dó sí ibi dáradára ṣùgbọ́n Efraimu yóò kó àwọn ọmọ rẹ̀ jáde fún àwọn apànìyàn.”
14 E Iehova, e haawi aku oe ia lakou i ka mea au e haawi aku ai; E haawi aku ia lakou i ka opu hanau hapa wale, a me na u maloo.
Fún wọn, Olúwa! Kí ni ìwọ yóò fún wọn? Fún wọn ní inú tí ń ba oyún jẹ́ àti ọyàn gbígbẹ.
15 O ko lakou hewa a pau, aia ma Gilegala; No ka mea, malaila au i inaina aku ai ia lakou: No ka hewa o ka lakou hana ana e kipaku aku ai au ia lakou mai ko'u hale aku, Aole au e aloha hou aku ia lakou, A o ko lakou mau alii, he poe kipi lakou!
“Nítorí gbogbo ìwà búburú tí wọ́n hù ní Gilgali, Mo kórìíra wọn níbẹ̀, nítorí ìwà ẹ̀ṣẹ̀ wọn. Èmi yóò lé wọn jáde ní ilé mi, Èmi kò ní ní ìfẹ́ wọn mọ́ ọlọ̀tẹ̀ ni gbogbo olórí wọn.
16 Ua hahauia o Eperaima, Ua maloo ko lakou aa; Aole lakou e hua mai ka hua; A ina e hanau mai lakou, E pepehi no au i na mea aloha o ko lakou opu.
Efraimu ti rẹ̀ dànù gbogbo rẹ̀ sì ti rọ, kò sì so èso. Bí wọ́n tilẹ̀ bímọ. Èmi ó pa àwọn ọmọ wọn tí wọ́n fẹ́ràn jùlọ.”
17 E kipaku auanei kuu Akua ia lakou, No ka mea, aole lakou i hoolohe ia ia; A e lilo lakou i poe aea mawaena o na lahuikanaka.
Ọlọ́run mi yóò kọ̀ wọ́n sílẹ̀ nítorí pé wọn kò gbọ́rọ̀ sí i; wọn yóò sì di alárìnkiri láàrín àwọn orílẹ̀-èdè.

< Hosea 9 >