< Hosea 2 >

1 O Ami, a i ko oukou mau hoahanau wahine, O Ruhama.
“Sọ fún àwọn arákùnrin rẹ, ‘Ènìyàn mi,’ kí o sì wí fún àwọn arábìnrin rẹ ‘Àyànfẹ́ mi.’
2 E hakaka oukou me ko oukou makuwahine, e hakaka oukou; No ka mea, aole oia o ka'u wahine; Aole hoi wau o kana kane: I haalele ai oia i kona hookamakama ana mai kona maka aku, A me kona moe kolohe hoi mai waena aku o kona mau u:
“Ẹ bá ìyá yín wí, ẹ bá a wí, nítorí pé kì í ṣe ìyàwó mi, Èmi náà kì í sì í ṣe ọkọ rẹ̀. Jẹ́ kí ó yọ àgbèrè rẹ̀ kúrò lójú rẹ̀ àti àìṣòótọ́ kúrò ní àyà rẹ̀.
3 O wehe aku au ia ia a olohelohe, A e hooku ia ia e like me ia i ka la ana i hanau ai, A e hoolilo ia ia e like me ka waoakua, A e hooku hoi ia ia e like me ka aina maloo, A e pepehi ia ia i ka makewai.
Àìṣe bẹ́ẹ̀ èmi yóò tú u sí ìhòhò, Èmi yóò sì gbé e kalẹ̀ bí ọjọ́ tí a bí i. Èmi yóò ṣe ọ́ bí i aṣálẹ̀ ilẹ̀, Èmi yóò sì sọ ọ́ di ìyàngbẹ ilẹ̀ Èmi yóò sì fi òǹgbẹ gbẹ ẹ́.
4 Aole au e aloha aku i kana poe keiki, No ka mea, he poe keiki lakou na ka moe kolohe.
Èmi kò ní fi àánú mi hàn sí àwọn ọmọ rẹ̀ nítorí ọmọ àgbèrè ni wọ́n jẹ́.
5 No ka mea, ua moe kolohe ko lakou makuwahine, Ua hana hilahila ka mea nana lakou i hapai: No ka mea, i iho la ia, E hele aku au mamuli o kuu mau ipo, Ka poe i haawi mai i ka'u ai, a me ko'u wai, i ko'u hulu hipa, a me kuu olona, o ko'u aila, a me ko'u mea inu.
Nítorí ìyá wọn ti hùwà àgbèrè, ó sì lóyún wọn nínú ìtìjú. Ó wí pé, ‘Èmi ó tún tọ́ àwọn àyànfẹ́ mi lẹ́yìn, tó ń fún mi ní oúnjẹ àti omi, ní irun àgùntàn mi àti ọ̀gbọ̀ mi, òróró mi àti ohun mímu mi.’
6 No ia mea, aia hoi, e hoopuni au i kou ala i na laau kuku, A e hana au i papohaku nona, I mea e loaa ole ai ia ia kona mau alanui.
Nítorí náà, èmi ó fi ẹ̀gún dì í lọ́nà, Èmi ó mọ odi yí i ká kí ó má ba à rọ́nà lọ.
7 A hahai aku no ia i kona mau hoaaloha, aole e loaa lakou ia ia; A imi aku hoi ia ia lakou, aole e loaa; Alaila, e i iho ia, E hele au, a e hoi hou i kuu kane mamua; No ka mea, ua oi aku ko'u pono i kela wa mamua o keia.
Yóò sáré lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ ṣùgbọ́n kò ní bá wọn; yóò wá wọn ṣùgbọ́n kò ní rí wọn. Nígbà náà ni yóò sọ pé, ‘Èmi ó padà sí ọ̀dọ̀ ọkọ mi àkọ́kọ́ nítorí pé ó dára fún mi nígbà náà ju ìsinsin yìí lọ.’
8 Aole oia i noonoo, ua haawi aku au ia ia i ka mea ai, a me ka waina hou. a me ka aila, A hoomahuahua aku hoi i ke kala, a me ke gula nona, Na mea a lakou i hoomakaukau ai no Baala.
Nítorí pé kò tí ì mọ̀ pé èmi ni àti ẹni tó fún un ní ọkà, ọtí wáìnì tuntun àti òróró ẹni tí ó fún un ní fàdákà àti wúrà lọ́pọ̀lọ́pọ̀, èyí tí wọ́n lò fún Baali.
9 No ia mea, e hoi hou mai au, a e lawe aku i ka'u palaoa i kona manawa, A me ka'u wain a hou i kona manawa iho, E lawe aku hoi au i ko'u hulu hipa, a me ko'u olona, na mea i uhi ai i kona olohelohe.
“Nítorí náà, èmi yóò mú ọkà mi kúrò nígbà tó bá pọ́n, èmi yóò sì mú wáìnì mi kúrò ní àsìkò rẹ̀. Èmi yóò sì gba irun àgùntàn àti ọ̀gbọ̀ mi padà ti mo ti fi fún un láti bo ìhòhò rẹ̀.
10 Ano e hoike aku au i kona mea hilahila imua o na maka o kona mau hoaaloha, Aohe mea e hoopakele ia ia mai ko'u lima aku.
Èmi yóò sì fi ìwà ìtìjú rẹ̀ hàn lójú àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ kò sí ẹni tí yóò gbà á sílẹ̀ lọ́wọ́ mi,
11 A e hoopau aku au i kona lealea a pau, I kana mau ahaaina, i kona mau mahina hou, i kona mau la Sabati. a me kona mau ahaaina a pau.
Èmi yóò mú gbogbo ayọ̀ rẹ̀ wá sí òpin: àjọ̀dún ọdọọdún rẹ̀, oṣù tuntun rẹ̀, ọjọ́ ìsinmi, àti gbogbo àwọn àjọ̀dún tí a yàn.
12 A e luku aku au i kona mau kumuwaina, a me kona mau laau fiku, i na mea ana i i mai ai, Oia ka'u uku, o ko'u mau ipo i haawi mai ai ia'u; A e hoolilo au ia mau mea i ululaau, A e ai iho na holoholona ia mau mea.
Èmi yóò pa àjàrà àti igi ọ̀pọ̀tọ́ rẹ̀ run, èyí tí ó pè ní èrè rẹ̀ láti ọ̀dọ̀ àwọn olólùfẹ́ rẹ̀, Èmi yóò sọ wọ́n di igbó, àwọn ẹranko búburú yóò sì jẹ́ wọn run.
13 A e hoopai aku au maluna ona i na la o na Baala, I na la ana i kuni ai i ka mea ala no lakou; A i kahiko ai ia ia iho i kona mau apo-ihu, a me kona mau lei-a-i, A hahai no ia mamuli o kona mau ipo, A hoopoina ia ia'u, wahi a Iehova.
Èmi yóò bẹ̀ ọjọ́ Baalimu wò ní ara rẹ̀ nínú èyí tó ń fi tùràrí jóná fún Baali; tí ó fi òrùka etí àti ohun ọ̀ṣọ́ rẹ̀, ṣe ara rẹ̀ lọ́ṣọ̀ọ́, tó sì tẹ̀lé àwọn olólùfẹ́ rẹ̀ lọ. Ṣùgbọ́n èmi ni òun gbàgbé,” ni Olúwa wí.
14 Nolaila, aia hoi, e hoowalewale au ia ia, a e alakai aku ia ia i ka waonahele, A e olelo oluolu aku ia ia.
“Nítorí náà, èmi yóò tàn án, Èmi ó sì mú u lọ sí ilẹ̀ aṣálẹ̀, Èmi ó fi pẹ̀lẹ́pẹ̀lẹ́ bá a sọ̀rọ̀
15 A e haawi aku au nona i kona mau malawaina mailaila mai, A i ke awawa o Akora, i puka o ka manaolana; A e mele no ia malaila, e like me ia i kona wa opio, A e like me ia i ka wa ana i puka mai ai mai ka aina o Aigupita mai.
Níbẹ̀ ni èmi yóò ti dá ọgbà àjàrà rẹ̀ padà fún un, Èmi yóò fi àfonífojì Akori ṣe ìlẹ̀kùn ìrètí fún un. Yóò sì kọrin níbẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà èwe rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìgbà tó kúrò ní Ejibiti.
16 A i kela manawa, wahi a Iehova, e kapa mai oe ia'u o Isi; Aole e kapa hou ia'u, o Baali.
“Yóò sì ṣe ní ọjọ́ náà, ìwọ yóò pè mí ní ‘ọkọ mi’; ìwọ kò sì ní pè mí ní ‘olúwa à mi mọ́,’ ni Olúwa wí.
17 A e lawe ae au i ka inoa o na Baala mai kona waha aku, Aole e hoomanao hou ia lakou ma ko lakou inoa.
Èmi yóò mú orúkọ, àwọn òrìṣà Baali kúrò lẹ́nu rẹ̀; ìwọ kò sì ní rí orúkọ òrìṣà Baali pè mọ́.
18 A i kela manawa e hana aku au no lakou i berita Me na holoholona o ke kula, a me na manu o ka lewa, A me na mea kolo o ka honua: A e haki ia'u ke kakaka, a me ka pahikaua, a me ka mea kaua mai ka honua aku, A e hoomoe iho au ia lakou me ka maluhia.
Ní ọjọ́ náà, èmi yóò ṣe májẹ̀mú fún wọn àti àwọn ẹranko igbó àti ẹyẹ ojú ọ̀run àti àwọn ẹ̀dá tí ń rìn lórí ilẹ̀. Kí wọn má bà á bẹ̀rù ara wọn mọ́. Ọfà, idà àti ogun jíjà ni èmi ó parun ní ilẹ̀ náà kí gbogbo ènìyàn bá a lè wà ní àìléwu.
19 E hoopalau aku au ia oe na'u a mau loa aku; A e hoopalau aku au ia oe na'u ma ka pono, a ma ka hoopono, a ma ka lokomaikai, a ma ke aloha.
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi títí láé; Èmi ó fẹ́ ọ ní ìwà òdodo àti òtítọ́, ní ìfẹ́ àti àánú.
20 A e hoopalau aku no hoi au ia oe na'u ma ka oiaio: A e ike aku oe ia Iehova.
Èmi yóò fẹ́ ọ fún ara mi ní òtítọ́ ìwọ yóò sì mọ Olúwa.
21 A i kela manawa, e hoolohe no au, wahi a Iehova, E hoolohe no au i na lani, a e hoolohe lakou i ka honua;
“Èmi yóò sì dáhùn ní ọjọ́ náà,” ni Olúwa wí; “Èmi yóò dá àwọn ọ̀run lóhùn àwọn ọ̀run yóò sì dá ilẹ̀ lóhùn;
22 A e hoolohe ka honua i ka ai, a me ka waina, a me ka aila; A e hoolohe no lakou ia Iezereela.
ilẹ̀ náà yóò sì dá ọkà, wáìnì tuntun àti òróró lóhùn Gbogbo wọn ó sì dá Jesreeli lóhùn.
23 A e kanu iho au ia ia ma ka honua; A e aloha aku au i ka mea i aloha ole ia; A e olelo aku au i ka poe kanaka aole no'u, O oe ko'u poe kanaka; A e olelo mai hoi lakou, O oe ko makou Akua.
Èmi ó sì gbìn ín fún ara mi lórí ilẹ̀ náà, Èmi yóò ṣàánú fún ẹni tí kò tì í ri ‘Àánú gbà.’ Èmi yóò sọ fún àwọn tí ‘Kì í ṣe ènìyàn mi pé,’ ‘Ẹ̀yin ni ènìyàn mi’; àwọn náà yóò sì wí pé, ‘Ìwọ ni Ọlọ́run mi.’”

< Hosea 2 >