< Kinohi 23 >

1 HOOKAHI haneri na makahiki me ka iwakaluakumamahiku o Sara: oia na makahiki o ke ola ana o Sara.
Sara sì pé ọmọ ọdún mẹ́tàdínláàádóje.
2 A make aku la o Sara ma Kiriatareba, oia o Heberona ma ka aina o Kanaana; a hele mai la o Aberahama e uwe a e kanikau ia Sara.
Ó sì kú ní Kiriati-Arba (ìyẹn ní Hebroni) ní ilẹ̀ Kenaani, Abrahamu lọ láti ṣọ̀fọ̀ àti láti sọkún nítorí Sara.
3 Ka ae la o Aberahama iluna, mai ke alo ae o kana mea i make, olelo aku la ia i na mamo a Heta, i aku la,
Abrahamu sì dìde lẹ́gbẹ̀ẹ́ òkú aya rẹ̀, ó sì sọ fún àwọn ará Hiti wí pé,
4 He malihini no wau e noho wale ana me oukou: e haawi mai i ilina iwaena o oukou, i lilo ia no'u, i kanu aku au i kuu mea i make, mai ko'u mau maka aku.
“Èmi jẹ́ àtìpó àti àlejò láàrín yín, ẹ ta ilẹ̀ ìsìnkú fún mi kí èmi le sin òkú tí ó kú fún mi sí.”
5 Olelo mai na mamo a Heta ia Aberahama, i mai la ia ia,
Àwọn ọmọ Hiti dá Abrahamu lóhùn pé,
6 E hoolohe mai oe i ka makou, e kuu haku: he alii nui no oe iwaena o makou; ma ka ilina maikai loa o makou, e kanu iho ai oe i kau mea make: aole e aua kekahi o makou i kona ilina ia oe, i ole oe e kanu i kou mea make.
“Olúwa mi, gbọ́ tiwa, ó jẹ́ alágbára ọmọ-aládé láàrín wa, sin òkú rẹ sí ibojì tí ó dára jù nínú àwọn ibojì wa, kò sí ẹni tí yóò fi ibojì rẹ dù ọ́ láti sin òkú rẹ sí.”
7 Ka ae la o Aberahama, a kulou iho la imua o na kanaka o ka aina, o na mamo a Heta.
Nígbà náà ni Abrahamu dìde, ó sì tẹríba níwájú àwọn ará ilẹ̀ náà, àwọn ará Hiti.
8 Kamailio aku la ia me lakou, i aku la, Ina o ko oukou manao ia, i kanu iho ai au i kuu mea make mai o'u mau maka aku; e hoolohe mai, a e noi aka oukou ia Eperona ke keiki a Zohara no'u;
Ó sì wí fún wọn pé, “Bí ó bá ṣe pé, lóòótọ́ ni ẹ fẹ́ kí n sin òkú mi kúrò nílẹ̀, ẹ gbọ́ tèmi, ẹ bá mi bẹ Efroni ọmọ Sohari,
9 I haawi mai ai oia i ke ana o Makepela no'u; nona no ia, aia no ma ka palena o kana mahinaai; no na kala e pono ke kuai, e haawi mai no oia ia wahi no'u i ilina iwaena o oukou.
kí ó ta ihò àpáta Makpela tí ó jẹ́ tirẹ̀ fún mi, èyí tí ó wà ni orí oko rẹ̀, kí ó tà á fún mi ni iye owó tí à ń ta irú rẹ̀ fún ilẹ̀ ìsìnkú láàrín yín.”
10 Noho pa iho la o Eperona me na mamo a Heta: olelo mai la o Eperona ka Heta ia Aberahama, ma ka lohe o na mamo a Heta, a o ka poe a pau i komo ma ka ipuka o ke kulanakauhale, i mai la,
Efroni ará Hiti sì wà níbẹ̀ pẹ̀lú, ó sì dá Abrahamu lóhùn lójú gbogbo àwọn ará ìlú tí ó wà níbẹ̀, lẹ́nu ibodè ìlú,
11 E kuu haku, e hoolohe mai oe ia'u: ke haawi wale aku nei au i ka mahinaai a me ke ana maloko, nou, ke haawi aku nei au nou ia wahi: imua o na keiki a o'u poe kanaka, ke haawi aku nei au nou ia wahi: e kanu aku oe i kau mea make.
pé, “Rárá, olúwa mi. Gbọ́ tèmi; mo fún ọ ní ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà níbẹ̀. Mo fún ọ níwájú gbogbo àwọn ènìyàn mi. Sin òkú rẹ síbẹ̀.”
12 Kulou iho la o Aberahama ilalo, imua o na kanaka o ia aina.
Abrahamu sì tún tẹríba níwájú àwọn ènìyàn ìlú náà,
13 I aku la oia ia Eperona ma ka lohe o na kanaka o ia aina, i ka i ana, Ke noi aku nei au ia oe, e hoolohe mai oe ia'u, Ina e ae mai oe, e haawi aku no wau i ke kala no ua mahinaai la; e lawe oe i ka'u, a e kanu no wau i kau mea make ilaila.
ó sì wí fún Efroni lójú gbogbo wọn pé, “Bí ìwọ bá fẹ́, gbọ́ tèmi, èmi yóò san owó ilẹ̀ náà, gbà á lọ́wọ́ mi kí n lè sin òkú mi síbẹ̀.”
14 Olelo mai la o Eperona ia Aberahama, i mai la ia ia,
Efroni sì dá Abrahamu lóhùn pé,
15 E kuu haku, e hoolohe mai ia'u, eha haneri sekela kala ke kumukuai o ia aina; heaha hoi ia iwaena o kaua? e kanu hoi oe i kau mea make.
“Gbọ́ tèmi Olúwa mi, irinwó òsùwọ̀n owó fàdákà ni ilẹ̀ náà, ṣùgbọ́n kín ni ìyẹn já mọ láàrín àwa méjèèjì? Sá à sin òkú rẹ.”
16 Ae mai la o Aberahama ia Eperona; a kaupouna iho la o Aberahama no Eperona i ke kala ana i olelo ai ma ka lohe o na mamo a Heta, eha haneri sekela kala, he kala pono i ka poe kuai.
Abrahamu sì gbọ́ tí Efroni wí, Abrahamu sì wọn iye fàdákà náà fún Efroni, tí ó sọ ní etí àwọn ọmọ Hiti, irinwó òsùwọ̀n ṣékélì fàdákà, tí ó kọjá lọ́dọ̀ àwọn oníṣòwò.
17 A ua hoolilo paa ia ka mahinaai a Eperona ma Makepela, ma ke alo o Mamere, o ka mahinaai me ke ana maloko, a me na laau a pau o na mahinaai la, a e puni ana ma na palena a pau,
Báyìí ni ilẹ̀ Efroni tí ó wà ni Makpela nítòsí Mamre, ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà nínú rẹ̀ àti gbogbo igi tí ó wà nínú ilẹ̀ náà ni a ṣe ètò rẹ̀ dájú,
18 No Aberahama i wahi nona ma ke alo o na mamo a Heta, imua hoi o ka poe a pau i komo ma ka ipuka o kona kulanakauhale.
bí ohun ìní fún Abrahamu níwájú gbogbo ará Hiti tí ó wá sí ẹnu ibodè ìlú náà.
19 Mahope iho, kanu iho la o Aberahama i kana wahine ia Sara iloko o ke ana ma ka mahinaai o Makepela ma ke alo o Mamere: oia o Heberona i ka aina o Kanaana.
Lẹ́yìn náà ni Abrahamu sin aya rẹ̀ Sara sínú ihò àpáta ní ilẹ̀ Makpela nítòsí Mamre (tí í ṣe Hebroni) ní ilẹ̀ Kenaani.
20 Ua hoolilo paa ia ka mahinaai a me ke ana maloko, no Aberahama i ilina nona, e na mamo a Heta.
Ilẹ̀ náà àti ihò àpáta tí ó wà nínú rẹ̀ ni àwọn ará Hiti fi fún Abrahamu gẹ́gẹ́ bí ohun ìní títí láé, bí ilẹ̀ ìsìnkú fún àwọn òkú tí ó bá kú fun un.

< Kinohi 23 >