< Ezera 2 >

1 EIA ka poe o ka mokuna i pii ae mai ka lawe pio ana mai, ka poe a Nebukaneza ke alii o Babulona i lawe pio aku ai i Babulona, a hoi hou mai la i Ierusalema a i Iuda, o kela kanaka keia kanaka i kona kulanakauhale iho;
Lákòókò náà, wọ̀nyí ni àwọn ènìyàn agbègbè Juda tí ó gòkè wá láti ìgbèkùn láàrín àwọn tí a kó lọ, ẹni tí Nebukadnessari ọba Babeli ti fi agbára mú ní ìgbèkùn lọ sí Babeli (wọ́n padà sí Jerusalẹmu àti Juda, olúkúlùkù sí ìlú rẹ̀.
2 Ka poe i kiki mai la me Zerubabela; Iesua, Nehemia, Seraia, Reelaia, Moredekai, Bilesana, Misepara, Bigevai, Rehuma, Baana. O ka helu ana keia o na kanaka o ka Iseraela:
Àwọn wọ̀nyí bá Serubbabeli, Jeṣua, Nehemiah, Seraiah, Reelaiah, Mordekai, Bilṣani, Mispari, Bigfai, Rehumu àti Baanah wá). Iye àwọn ọkùnrin àwọn ènìyàn Israẹli.
3 O na mamo a Parosa, elua tausani, hookahi haneri a me kanahikukumamalua.
Àwọn ọmọ Paroṣi jẹ́ ẹgbàá ó lé méjìléláàádọ́sàn-án
4 O na mamo a Sepatia, ekolu haneri a me kanahikukumamalua.
Ṣefatia jẹ́ òjìdínnírinwó ó lé méjìlá
5 O na mamo a Ara, ehiku haneri a me kanahikukumamalima.
Arah jẹ́ ẹgbẹ̀rin ó dín mẹ́ẹ̀ẹ́dọ́gbọ̀n
6 O na mamo a Pahatamoaba, na na keiki a Iesua, a me Ioaba, elua tausani, awalu haneri a me ka umikumamalua.
Pahati-Moabu (láti ipasẹ̀ àwọn ọmọ Jeṣua àti Joabu) jẹ́ ẹgbẹ̀rún méjì àti ẹgbẹ̀rin lé méjìlá
7 O na mamo a Elama, hookahi tausani, elua haneri a me kanalimakumamaha.
Elamu jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀fà ó lé mẹ́rin
8 O na mamo a Zatu eiwa haneri a me kanahakumamalima.
Sattu jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rún ó lé márùn-ún
9 O na mamo a Zakai, ehiku haneri a me kanaono.
Sakkai jẹ́ òjìdínlẹ́gbẹ̀rin
10 O na mamo a Bani, eono haneri a me kanahakumamalua.
Bani jẹ́ òjìlélẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì
11 O na mamo a Behai, eono haneri a me ka iwakaluakumamakolu.
Bebai jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mẹ́tàlélógún
12 O na mamo a Azegada, hookahi tausani, elua haneri a me ka iwakaluakumamalua.
Asgadi jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé méjìlélógún
13 O na mamo a Adonikama, eono haneri a me kanaonokumamaono.
Adonikami jẹ́ ọ̀tàlélẹ́gbẹ̀ta ó lé mẹ́fà
14 O na mamo a Bigevai, elua tausani a me kanalimakumamaono.
Bigfai jẹ́ ẹgbàá ó lé mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
15 O na mamo a Adina, eha haneri a me kanalimakumamaha.
Adini jẹ́ àádọ́ta lé ní irinwó ó lé mẹ́rin
16 O na mamo a Atera na Hezekia, he kanaiwakumamawalu.
Ateri (nípasẹ̀ Hesekiah) jẹ́ méjìdínlọ́gọ́run
17 O na mamo a Bezai, ekolu haneri a me ka iwakaluakumamakolu.
Besai jẹ́ ọrùndínnírinwó ó lé mẹ́ta
18 O na mamo a Iora, hookahi haneri a me ka umikumamalua.
Jora jẹ́ méjìléláàádọ́fà
19 O na mamo a Hasuma, elua haneri a me ka iwakaluakumamakolu.
Haṣumu jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
20 O na mamo a Gibara, he kanaiwakumamalima.
Gibbari jẹ́ márùndínlọ́gọ́rùn.
21 O na mamo a Betelehema, hookahi haneri a me ka iwakaluakumamakolu.
Àwọn ọmọ Bẹtilẹhẹmu jẹ́ mẹ́tàlélọ́gọ́fà
22 O na kanaka o Netopa, he kanalimakumamaono.
Netofa jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́ta
23 O na kanaka o Anatota, hookahi haneri a me ka iwakaluakumamawalu.
Anatoti jẹ́ méjìdínláàádóje
24 O na mamo a Azemaveta, he kanahakumamalua.
Asmafeti jẹ́ méjìlélógójì
25 O na mamo a Kiriatarima, Kepira a me Beerota, ehiku haneri a me kanahakumamakolu.
Kiriati-Jearimu, Kefira àti Beeroti jẹ́ ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó lé mẹ́ta
26 O na mamo a Rama a me Gaba, eono haneri a me ka iwakaluakumamakahi.
Rama àti Geba jẹ́ ẹgbẹ̀ta ó lé mọ́kànlélógún
27 O na kanaka o Mikemase, hookahi haneri a me ka iwakaluakumamalua.
Mikmasi jẹ́ méjìlélọ́gọ́fà
28 O na kanaka o Betela, a o Ai, elua haneri a me ka iwakaluakumamakolu.
Beteli àti Ai jẹ́ igba ó lé mẹ́tàlélógún
29 O na mamo a Nebo, he kanalimakumamalua.
Nebo jẹ́ méjìléláàádọ́ta
30 O na mamo a Magebisa, hookahi haneri a me kanalimakumamaono.
Magbiṣi jẹ́ mẹ́rìndínlọ́gọ́jọ
31 O na mamo a kela Elama, hookahi tausani, elua haneri a me kanalimakumamaha.
Elamu mìíràn jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́rìnléláàádọ́ta
32 O na mamo a Harima, ekolu haneri a me ka iwakalua.
Harimu jẹ́ ọ̀rìndínnírinwó.
33 O na mamo a Loda, o Hadida a me Ono, ehiku haneri a me ka iwakaluakumamalima.
Lodi, Hadidi àti Ono jẹ́ ọ̀rìndínlẹ́gbẹ̀rin ó lé márùn-ún
34 O na mamo a Ieriko, ekolu haneri a me kanahakumamalima.
Jeriko jẹ́ ọ̀tàdínnírinwó ó lé márùn-ún
35 O na mamo a Senaa, ekolu tausani, eono haneri a me kanakolu.
Senaa jẹ́ egbèji dín lógún ó lé ọgbọ̀n.
36 O na kahuna: o na mamo a Iedaia, no ka hale o Iesua, eiwa haneri a me kanahikukumamakolu.
Àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ Jedaiah (láti ipasẹ̀ ìdílé Jeṣua) jẹ́ ogún dín lẹ́gbẹ̀rin ó dín méje
37 O na mamo a Imera, hookahi tausani a me kanalimakumamalua.
Immeri jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀rún ó lé méjì
38 O na mamo a Pasehura, hookahi tausani, elua haneri a me kanahakumamahiku.
Paṣuri jẹ́ ẹgbẹ̀fà ó lé mẹ́tàdínláàádọ́ta
39 O na mamo a Harima, hookahi tausani a me ka umikumamahiku.
Harimu jẹ́ ẹgbẹ̀rún ó lé mẹ́tàdínlógún.
40 O na Levi; o na mamo a Iesua, na Kademiela, a na na keiki a Hodavia, he kanahikukumamaha.
Àwọn ọmọ Lefi. Àwọn ọmọ Jeṣua àti Kadmieli (ti ìdílé Hodafiah) jẹ́ mẹ́rìnléláàádọ́rin.
41 O ka poe mele; o na mamo a Asepa, hookahi haneri a me ka iwakaluakumamawalu.
Àwọn akọrin. Àwọn ọmọ Asafu jẹ́ méjìdínláàádóje.
42 O na mamo a na kiaipuka; o na mamo a Saluma, o na mamo a Atera, o na mamo a Talemona, o na mamo a Akuba, o na mamo a Hatita, o na mamo a Sobai, o lakou a pau, hookahi haneri a me kanakolukumamaiwa.
Àwọn aṣọ́bodè. Àwọn ará Ṣallumu, Ateri, Talmoni, Akkubu, Hatita àti Ṣobai jẹ́ mọ́kàndínlógóje.
43 O ka poe Netini; o na mamo a Ziha, o na mamo a Hasupa, o na mamo a Tabaota,
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili. Àwọn ọmọ. Siha, Hasufa, Tabboati,
44 O na mamo a Kerosa, o na mamo a Siaha, o na mamo a Padona,
Kerosi, Siaha, Padoni,
45 O na mamo a Lehana, o na mamo a Hagaba, o na mamo a Akuba,
Lebana, Hagaba, Akkubu,
46 O na mamo a Hagaba, o na mamo a Salemai, o na mamo a Hanana,
Hagabu, Ṣalmai, Hanani,
47 O na mamo a Gidela, o na mamo a Gahara, o na mamo a Reaia,
Giddeli, Gahari, Reaiah,
48 O na mamo a Rezina, o na mamo a Nekoda, o na mamo a Gazama,
Resini, Nekoda, Gassamu,
49 O na mamo a Uza, o na mamo a Pasea, o na mamo a Besai,
Ussa, Pasea, Besai,
50 O na mamo a Asena, o na mamo a Mehunima, o na mamo a Nepusima,
Asna, Mehuni, Nefisimu,
51 O na mamo a Bakebuka, o na mamo a Hakupa, o na mamo a Harehura,
Bakbu, Hakufa, Harhuri.
52 O na mamo a Bazeluta, o na mamo a Mehida, o na mamo a Haresa,
Basluti, Mehida, Harṣa,
53 O na mamo a Barekosa, o na mamo a Sisera, o na mamo a Tama,
Barkosi, Sisera, Tema,
54 O na mamo a Nezia, o na mamo a Hatipa.
Nesia àti Hatifa.
55 O na mamo a na kauwa a Solomona; o na mamo a Sotai, o na mamo a Sopereta, o na mamo a Peruda.
Àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni. Àwọn ọmọ Sotai, Sofereti, Peruda,
56 O na mamo a Iaala, o na mamo a Darekona, o na mamo a Gidela,
Jaala, Darkoni, Giddeli,
57 O na mamo a Sepatia, o na mamo a Hatila, o na mamo a Pokereta no Zehaima, o na mamo a Ami.
Ṣefatia, àwọn ọmọ Hattili, Pokereti ti Haṣebaimu àti àwọn ọmọ Ami.
58 O ka poe Netini a pau, a me na mamo a na kauwa a Solomona, ekolu haneri, a me kanaiwakumamalua.
Àwọn ìránṣẹ́ tẹmpili àti àwọn ọmọ àwọn ìránṣẹ́ Solomoni jẹ́ irinwó ó dín mẹ́jọ.
59 A eia na mea i pii ae mailoko aku o Telemela, o Teleharesa, o Keruba, o Adana, o Imera; aole e hiki ia lakou ke hoike aku i ka ohana makua, aole hoi i ko lakou hanauna, i ikea no ka Iseraela paha lakou.
Àwọn wọ̀nyí gòkè wá láti àwọn ìlú ti Teli-Mela, Teli-Harṣa, Kerubu, Addoni àti Immeri, ṣùgbọ́n wọn kò lè sọ pẹ̀lú ìdánilójú pé ìdílé àwọn wá láti ara ìran ẹ̀yà Israẹli.
60 O na mamo a Delaia, o na mamo a Tobia, o na mamo a Nekoda, eono haneri a me kanalimakumamalua.
Àwọn ọmọ Delaiah, Tobiah àti Nekoda jẹ́ àádọ́ta lé lẹ́gbẹ̀ta ó lé méjì.
61 O na mamo a na kahuna; o na mamo a Habaia, o na mamo a Koza, o na mamo a Barezilai, nana i lawe i wahine no na kaikamahine a Barezilai, no Gileada, a ua kapaia oia mamuli o ko lakou inoa.
Àti nínú àwọn ọmọ àwọn àlùfáà. Àwọn ọmọ: Hobaiah, Hakosi àti Barsillai (ọkùnrin tí ó fẹ́ ọmọbìnrin Barsillai ará Gileadi a sì ń fi orúkọ náà pè é).
62 Imi aku la keia poe i ka lakou kuauhau iwaena o ka poe i kakauia, aole i loaa ia; a ua hookaawaleia lakou mai ka oihanakahuna aku.
Àwọn wọ̀nyí wá ìwé ìrántí ìdílé wọn, ṣùgbọ́n wọn kò rí i, bẹ́ẹ̀ ni a kò kà wọ́n kún ara àlùfáà nítorí, a kà wọ́n sí aláìmọ́.
63 A olelo aku la ke kiaaina ia lakou, aole lakou e ai i na mea i hoolaa loa ia, a ku mai kekahi kahuna me ka Urima a me ke Tumima.
Baálẹ̀ pa á láṣẹ fún wọn pé wọn kò gbọdọ̀ jẹ nínú oúnjẹ mímọ́ jùlọ títí tí àlùfáà kan yóò fi ṣiṣẹ́ ìránṣẹ́ pẹ̀lú Urimu àti Tumimu.
64 A o ka ahakanaka a pau, i akoakoa, he kanahakumamalua tausani, ekolu haneri a me kanaono;
Gbogbo ìjọ ènìyàn náà jẹ́ ẹgbàá mọ́kànlélógún ó lé òjìdínnírinwó.
65 He okoa ka lakou poe kauwa kane, a me ka lakou poe kauwawahine, ehiku tausani lakou, ekolu haneri a me kanakolukumamahiku: a o ka poe kane mele o lakou, a me ka poe wahine mele, elua haneri lakou.
Yàtọ̀ sí ẹgbẹ̀rin dín lẹ́gbàárin ó dín mẹ́tàlélọ́gọ́ta ìránṣẹ́ ọkùnrin àti ìránṣẹ́bìnrin; wọ́n ní igba akọrin ọkùnrin àti obìnrin.
66 A o na lio o lakou, ehiku haneri a me kanakolukumamaono; a o na hoki o lakou, elua haneri a me kanabakumamalima.
Wọ́n ní ọ̀tàdínlẹ́gbẹ̀rin ó dín mẹ́rin ẹṣin; ìbáaka òjìlélúgba ó lé márùn-ún,
67 A o ko lakou poe kamelo, eha haneri, a me kanakolukumamalima; a o na miula, eono tausani, ehiku haneri, a me ka iwakalua.
ràkunmí jẹ́ irinwó ó lé márùndínlógójì àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ ẹgbẹ̀rin lé lọ́gbọ̀n ó dín ọgọ́rin.
68 A o kekahi poe koikoi o na makua, i ko lakou hele ana i ka hale o Iehova ma Ierusalema, haawi oluolu aku la lakou no ka hale o ke Akua, e hana aku ia mea ma kona wahi:
Ní ìgbà tí wọ́n dé ilé Olúwa ní Jerusalẹmu, díẹ̀ nínú àwọn olórí àwọn ìdílé fi ọrẹ àtinúwá sílẹ̀ fún ṣíṣe àtúnkọ́ ilé Ọlọ́run ní ààyè rẹ̀.
69 E like me ko lakou waiwai, pela lakou i haawi aku ai iloko o ka waihonawaiwai no ka hana, i kanaonokumamakahi tausani derama gula, a i elima tausani mane kala, a me ka haneri hookahi o na lole komo no na kahuna.
Gẹ́gẹ́ bí agbára wọn, wọ́n fún ilé ìṣúra fún iṣẹ́ yìí ní ọ̀kẹ́ mẹ́ta ó lé lẹ́gbẹ̀rún ìwọ̀n dariki wúrà, ẹgbẹ̀rún márùn-ún fàdákà àti ọgọ́rùn-ún ẹ̀wù àlùfáà.
70 A o na kahuna a me na Levi, a me kekahi o na kanaka, a me ka poe mele, a me ka poe kiaipuka, a me ka poe Netini, noho iho la ma ko lakou mau kulanakauhale, a o ka Iseraela a pau ma ko lakou mau kulanakauhale.
Àwọn àlùfáà, àwọn ará Lefi, àwọn akọrin, àwọn aṣọ́bodè àti àwọn ìránṣẹ́ ilé Olúwa ṣe àtìpó sínú àwọn ìlú wọn, pẹ̀lú àwọn ènìyàn mìíràn, àti ìyókù àwọn ọmọ Israẹli ṣe àtìpó sínú ìlú u wọn.

< Ezera 2 >