< Ezekiela 8 >

1 EIA hoi keia i ke ono o ka makahiki, i ka malama aono, i ka la alima o ka malama, e noho ana au iloko o kuu hale, a noho no na lunakahiko o ka Iuda imua o'u, haule mai ka lima o Iehova ka Haku malaila, maluna o'u.
Ní ọjọ́ karùn-ún, oṣù kẹfà ọdún kẹfà bí mo ṣe jókòó nílé mi pẹ̀lú àwọn àgbàgbà Juda níwájú mi, ọwọ́ Olúwa Olódùmarè bà lé mi níbẹ̀.
2 Alaila nana aku au, aia hoi he mea ua like ke ano me ke ahi i ka nana aku; mai ka ikea ana o kona puhaka ilalo, he ahi; a mai kona puhaka iluna, me he olinolino la ke nana aku, a me ke keleawe hoohualiia.
Nígbà tí mo wò, mo rí ohun kan tí ó jọ ènìyàn. Láti ibi ìbàdí rẹ lọ sísàlẹ̀ dàbí iná, láti ibi ìbàdí yìí sókè sì mọ́lẹ̀ bí idẹ tó ń kọ mọ̀nà.
3 Kikoo mai la oia i ka mea like me ka lima, a lalau mai ia'u ma kekahi wili lauoho o kuu poo, a kaikai ae ka uhane ia'u iluna mawaena o ka honua a me ka lani, a alakai ae la ia'u i Ierusalema ma na hihio o ke Akua, i ka pani o ka pukapa iloko e nana ana i ke kukulu akau, kahi o ke kii e lili ai ka mea hoolili.
Ó na ohun tó dàbí ọwọ́ jáde, ó fi gba mi ní irun orí mú, Ẹ̀mí sì gbé mi sókè sí agbede-méjì ayé àti ọ̀run, ó sì mú mi lọ rí ìran Ọlọ́run, mo sì lọ sí Jerusalẹmu, ṣí ìlẹ̀kùn ẹnu-ọ̀nà òde àríwá níbi tí ère owú tí ó ń mú ni bínú wá níwájú mi.
4 Aia hoi, malaila ka nani o ke Akua o Iseraela, e like me ka hihio a'u i ike ai ma ka papu.
Sì kíyèsi i, ògo Ọlọ́run Israẹli wà níbẹ̀, gẹ́gẹ́ bí ìran ti mo rí ni pẹ̀tẹ́lẹ̀.
5 Alaila olelo mai la oia ia'u, E ke keiki a ke kanaka, Ealawa ae i kou mau maka ma ke kukulu akau. Alawa ae la hoi au i kau mau maka i ke kukulu akau, aia hoi ma ke kukulu akau ma ka puka o ke kuahu keia kii e lili ai, maloko o kahi e komo ai.
Ó sì sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbójú sókè sí ìhà àríwá.” Èmi náà sì gbójú sókè sí ìhà àríwá mo sì rí ère tí ó ń mú ni jowú ní ẹnu-ọ̀nà ibi pẹpẹ.
6 A olelo hou mai la ia, E ke keiki a ke kanaka, ke ike nei anei oe i ka mea a lakou e hana nei? na mea e inainaia a ka ohana a Iseraela i hana'i ma keia wahi, i hele loihi aku ai au mai ko'u keenakapu aku? Aka, e haliu hou ae oe, a e ike oe i na mea e inainaia he nui aku.
Ó sì wí fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o rí ohun tí wọ́n ń ṣe ohun ìríra ńlá tí ilé Israẹli ń ṣe, láti lé mi jìnnà réré sí ibi mímọ́ mi? Ṣùgbọ́n ìwọ yóò tún rí àwọn ìríra ńlá tó tóbi jù èyí lọ.”
7 A lawe mai oia ia'u ma ka puka o ka pahale, a nana aku au, aia hoi he puka maloko o ka pa.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà àgbàlá. Mo wò ó, mo sì rí ihò kan lẹ́gbẹ̀ẹ́ ògiri.
8 Olelo mai la hoi oia ia'u, E ke keiki a ke kanaka, e pao ae oe maloko o ka pa. A pao ae la au iloko o ka pa, aia hoi he ipuka.
Nígbà náà ló sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, gbẹ́ inú ògiri náà,” nígbà tí mo sì gbẹ́ inú ògiri, mo rí ìlẹ̀kùn kan.
9 I mai la hoi ia ia'u, E komo ae oe iloko, a e nana oe i na mea hewa e inainaia a lakou e hana nei maanei.
Ó sì wí fún mi pé, “Wọlé kí ìwọ kí ó rí ohun ìríra búburú tí wọ́n ń ṣe níbẹ̀.”
10 Komo ae la hoi au a ike, aia hoi o ke ano o na mea kolo a pau me na holoholona i hoopailuaia, a me na akuakii o ka ohana a Iseraela i kakauia ma ka pa a puni.
Mo wọlé, mo sì rí àwòrán oríṣìíríṣìí ẹranko tí ń fà nílẹ̀ àti àwọn ẹranko ìríra àti gbogbo òrìṣà ilẹ̀ Israẹli tí wọ́n yà sára ògiri.
11 Ku mai la imua o lakou na kanaka he kanahiku o na lunakahiko o ka ohana a Iseraela, a iwaenakonu o lakou e ku ana o Iaazania, ke keiki a Sapana, e paa ana kela kanaka keia kanaka i kona kapuahi kuni mea ala i kona lima. Punohu nui ae la ka uahi mea ala paapu.
Níwájú wọn ni àádọ́rin ọkùnrin tó jẹ́ àgbàgbà ilé Israẹli dúró sí, Jaaṣaniah ọmọ Ṣafani sì dúró sí àárín wọn. Ọ̀kọ̀ọ̀kan wọn sì mú àwo tùràrí lọ́wọ́, òórùn sì ń tú jáde.
12 Alaila olelo mai la oia ia'u, E ke keiki a ke kanaka, ua ike anei oe i ka mea a na lunakahiko o ka ohana a Iseraela e hana nei iloko o ka pouli, kela kanaka keia kanaka iloko o kona keena e nana ai? No ka mea, ke olelo nei lakou, Aole ike mai o Iehova; ua haalele Iehova i ka honua.
Ó sọ fún mi pé, “Ọmọ ènìyàn, ṣé o ti rí ohun tí àwọn àgbàgbà ilé Israẹli ń ṣe nínú òkùnkùn, olúkúlùkù ní yàrá òrìṣà rẹ̀? Wọ́n ní, ‘Olúwa kò rí wa; Olúwa ti kọ̀ ilé náà sílẹ̀.’”
13 Olelo mai la oia ia'u, E haliu hou ae oe, a e ike oe i na mea e inainaia he nui aku a lakou e hana nei.
Ó tún sọ fún mi pé, “Ìwọ yóò rí wọn tí wọ́n ń ṣe àwọn ohun ìríra tó burú jù bẹ́ẹ̀ lọ.”
14 Alaila lawe mai oia ia'u i ke pani o ka ipuka pa o ka hale o Iehova, ka mea ma ka aoao kukulu akau; aia hoi, e noho ana na wahine e uwe ana no Tamuza.
Ó mú mi wá sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sí ẹnu-ọ̀nà ilé Olúwa tó wà ní ìhà àríwá, mo sì rí àwọn obìnrin tó jókòó, tí wọ́n sì ń ṣọ̀fọ̀ fún Tamusi.
15 Ninau mai la oia ia'u, Ua ike anei oe i keia, e ke keiki a ke kanaka? E haliu hou ae oe a e ike oe i na mea e inainaia e oi aku mamua o keia.
Ó sọ fún mi pé, “Ṣé ìwọ rí báyìí, ọmọ ènìyàn? Ìwọ yóò tún rí ìríra tó ga jù èyí lọ.”
16 Lawe ae la oia ia'u iloko o ka pahale loko o ka hale o Iehova, aia hoi, ma ka puka o ka luakini o Iehova mawaena o ka lanai a me ke kuahu, he iwakaluakumamalima paha o na kanaka, ua huli ko lakou mau kua i ka luakini o Iehova, a o ko lakou mau alo i ka hikina; a hoomana aku la lakou i ka la ma ka hikina.
Ó mú mi wá sí ibi àgbàlá ilé Olúwa, ní ẹnu-ọ̀nà tẹmpili Olúwa, láàrín ìloro àti pẹpẹ, ni ìwọ̀n ọkùnrin mẹ́ẹ̀dọ́gbọ̀n wà, tí wọ́n kẹ́yìn sí tẹmpili Olúwa tí wọn sì kọjú sí ìlà-oòrùn, wọ́n sì ń foríbalẹ̀ fún oòrùn ní apá ìlà-oòrùn.
17 Alaila ninau mai la ia ia'u, Ua ike anei oe i keia, e ke keiki a ke kanaka? He mea mama anei i ka ohana a Iuda ka lakou hana ana i na mea e inainaia a lakou e hana nei maanei? no ka mea, ua hoopiha lakou i ka aina i ka hewa, a ua huli mai lakou e hoonaukiuki mai ia'u; aia hoi, ua kau lakou i ka lala ma ko lakou ihu.
Ó sì wí fún mi, “Ṣé ìwọ ti rí èyí ọmọ ènìyàn? Ǹjẹ́ ohun kékeré ni fún ilé Juda láti ṣe àwọn ohun ìríra tí wọn ń ṣe níbi yìí? Ṣé o tún yẹ kí wọ́n fi ìwà ipá kún ilẹ̀ kí wọn sì máa mú mi bínú ní gbogbo ìgbà? Wò wọn bi wọn ṣe n fi ẹ̀ka wọn sínú inú wọn.
18 Nolaila owau no kekahi e hana aku me ka ukiuki; aole e aloha kuu maka, aole hoi au e menemene aku; a ina e kahea lakou iloko o ko'u mau pepeiao me ka leo nui, aole au o hoolohe aku ia lakou.
Nítorí náà, èmi yóò fi ìbínú bá wọn wí; èmi kò ní i dá wọn sí bẹ́ẹ̀ ni èmi kò sì ní fojú àánú wò wọ́n. Bí wọ́n tilẹ̀ ń pariwo sí mi létí, èmi kò ní fetí sí wọn.”

< Ezekiela 8 >