< Ezekiela 30 >

1 HIKI mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tún tọ̀ mí wá: wí pé:
2 E ke keiki a ke kanaka, e wanana, a e olelo aku, Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; E auwe oukou, auwe ka la!
“Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí o sì wí pé: ‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Hu, kí o sì wí pé, “Ó ṣe fún ọjọ́ náà!”
3 No ka mea, ua kokoke mai ka la, kokoke mai ka la o Iehova, ka la paapu i ke ao; e lilo ia i manawa no na lahuikanaka.
Nítorí ọjọ́ náà súnmọ́ tòsí àní ọjọ́ Olúwa súnmọ́ tòsí, ọjọ́ tí ọjọ́ ìkùùkuu ṣú dúdú, àsìkò ìparun fún àwọn kèfèrí.
4 E hiki ae no hoi ka pahikaua maluna o Aigupita, a e nui auanei ka weliweli maluna o Aitiopa, i ka wa e haule ai ka poe i pepehiia ma Aigupita, a e lawe aku ai hoi lakou i kona lehulehu a wawahiia kona mau kumu ilalo.
Idà yóò wá sórí Ejibiti ìrora ńlá yóò sì wá sórí Kuṣi. Nígbà tí àwọn tí a pa yóò ṣubú ní Ejibiti wọn yóò kò ọrọ̀ rẹ̀ lọ ìpìlẹ̀ rẹ̀ yóò sì wó lulẹ̀.
5 O Aigupita, a me Puta, a me Ludia, a me na kanaka huipuia a pau, a me Kuba, a me na kanaka o ka aina iloko o ke kuikahi, o lakou ke haule pu me lakou, ma ka pahikaua.
Kuṣi àti Puti, Libia, Ludi àti gbogbo Arabia, Kubu àti àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà tí ó mulẹ̀ yóò ṣubú nípa idà pẹ̀lú Ejibiti.
6 Ke i mai nei Iehova penei; E haule no hoi ka poe kokua ia Aigupita, a e iho iho ka haaheo o kona ikaika ilalo; mai ka halekiai o Seena e haule ai lakou ma ka pahikaua iloko ona, wahi a Iehova ka Haku.
“‘Èyí yìí ní Olúwa wí: “‘Àwọn àlejò Ejibiti yóò ṣubú agbára ìgbéraga rẹ yóò kùnà láti Migdoli títí dé Siene, wọn yóò ti ipa idà ṣubú nínú rẹ; ní Olúwa Olódùmarè wí.
7 A e neoneo lakou iwaena o na aina neoneo, a iwaena hoi kona mau kulanakauhale o na kulanakauhale i hooneoneoia.
Wọn yóò sì wà lára àwọn ilẹ̀ tí ó di ahoro, ìlú rẹ yóò sì wà ní ara àwọn ìlú tí ó di ahoro.
8 A e ike lakou owau no Iehova, aia hoonoho au i ke ahi iloko o Aigupita, a e pau hoi kona mau kokua i ka uhaiia.
Lẹ́yìn náà wọn yóò mọ̀ pé èmi ní Olúwa, nígbà tí mo bá gbé iná kalẹ̀ ní Ejibiti tí gbogbo àwọn olùrànlọ́wọ́ rẹ̀ bá parun.
9 Ia la no e holo aku na elele mai o'u aku nei ma na moku e hoomakau i ko Aitiopa poe nanea, a e hiki ae ka eha nui maluna o lakou, e like me ia i na la o Aigupita; no ka mea, eia'e, ke hele mai ia.
“‘Ní ọjọ́ náà oníṣẹ́ yóò ti ọ̀dọ̀ mi jáde nínú ọkọ̀ ojú omi láti dẹ́rùbà Kuṣi tí ó wà nínú àlàáfíà. Ìrora yóò wá sórí wọn gẹ́gẹ́ bí ti ọjọ́ ìparun Ejibiti. Kíyèsi i, ó dé.
10 Ke i mai nei Iehova ka Haku, E hooki au i ka lehulehu o Aigupita ma ka lima o Nebukaneza ke alii o Babulona.
“‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi yóò mú òpin bá ọ̀gọ̀ọ̀rọ̀ àwọn ènìyàn Ejibiti láti ọwọ́ Nebukadnessari ọba Babeli.
11 Oia, a me kona poe kanaka me ia, o na mea e weliweli ai o na lahuikanaka, e laweia'e lakou e hokai i ka aina; a e unuhi ku e ae lakou i ka lakou mau pahikaua ia Aigupita, a e hoopaapu i ka aina me ka poe i pepehiia.
Òun àti àwọn ológun rẹ̀ ẹ̀rù àwọn orílẹ̀-èdè ní a o mú wá láti pa ilẹ̀ náà run. Wọn yóò fa idà wọn yọ sí Ejibiti ilẹ̀ náà yóò sì kún fún àwọn tí a pa.
12 E hoomaloo aku au i na muliwai, a e kuai lilo aku i ka aina iloko o ka lima o ka poe hewa; a e hooneoneo aku au i ka aina a me ko laila a pau ma ka lima o na malihini: na'u na Iehova i olelo aku.
Èmi yóò mú kí àwọn odò Naili gbẹ, Èmi yóò sì ta ilẹ̀ náà fún àwọn ènìyàn búburú: láti ọwọ́ àwọn àjèjì ènìyàn, Èmi yóò jẹ́ kí ilẹ̀ náà àti gbogbo ohun tí ó wá nínú rẹ ṣòfò. Èmi Olúwa ni ó ti sọ ọ́.
13 Ke i mai nei Iehova ka Haku, E hokai au i na akuakii, a e hooki au i na kii mai loko aku o Nopa; aole loa hoi ke alii hou o ka aina Aigupita; a haawi au i ka makau ma ka aina Aigupita.
“‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: “‘Èmi yóò pa àwọn òrìṣà run, Èmi yóò sì mú kí òpin dé bá ère gbígbẹ́ ni Memfisi. Kò ní sí ọmọ-aládé mọ́ ní Ejibiti, Èmi yóò mú kí ìbẹ̀rù gba gbogbo ilẹ̀ náà.
14 E hooneoneo hoi au ia Paterosa, a e haawi i ke ahi iloko o Zoana, a e hoopai hoi maloko o No.
Èmi yóò sì mú kí Paturosi di ahoro, èmi yóò fi iná sí Ṣoani, èmi yóò sì fi ìyà jẹ Tebesi.
15 E ninini hoi au i kuu ukiuki maluna o Sina, ka ikaika o Aigupita; a e oki aku au i ka lehulehu o No.
Èmi yóò tú ìbínú mi jáde sórí Pelusiumu ìlú odi Ejibiti èmi yóò sì ké àkójọpọ̀ Tebesi kúrò.
16 A e haawi aku au i ke ahi iloko o Aigupita, he eha nui auanei ko Sina, a e hookaawaleia'e o No, a e pilikia hoi o Nopa i kela la i keia la.
Èmi yóò ti iná bọ Ejibiti Pelusiumu yóò japoró ní ìrora. Ìjì líle yóò jà ní Tebesi Memfisi yóò wà ìpọ́njú ní ìgbà gbogbo.
17 A e haule ma ka pahikaua ko Avena a me ko Pibeseta poe kanaka ui, a e hele laua i ke pio ana.
Àwọn ọ̀dọ́mọkùnrin ní Heliopolisi àti Bubasiti yóò ti ipa idà ṣubú wọn yóò sì kó àwọn ìlú wọn ní ìgbèkùn.
18 Ma Tehapenesa e hoopouliia ka la i ka wa e uhaki ai au ilaila i na auamo o Aigupita; a e oki ka hanohano o kona ikaika iloko ona: a oia hoi, e uhi mai kahi ao maluna ona, a e hele kana mau kaikamahine i ke pio ana.
Ojú ọjọ́ yóò ṣókùnkùn ní Tafanesi nígbà tí mo bá já àjàgà Ejibiti kúrò; níbẹ̀ agbára iyì rẹ̀ yóò dópin wọn yóò fi ìkùùkuu bò ó àwọn abúlé rẹ ní wọn yóò lọ sí ìgbèkùn.
19 A e hoopai au ma Aigupita; a a e ike lakou, owau no Iehova.
Nítorí náà, Èmi yóò mú ki ìjìyà wá sórí Ejibiti, wọn yóò sì mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.’”
20 Eia hoi keia, i ka umikumamakahi o ka makahiki, i ka malama mua, i ka la ahiku o ka malama, hiki mai ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ní ọjọ́ keje oṣù kìn-ín-ní ọdún kọkànlá ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá,
21 E ke keiki a ke kanaka, ua uhaki au i ka lima o Parao ke alii o Aigupita, aole ia e wahiia e hoolaia'i, e kau i ka lole wili e wahi ai ia mea, e hooikaika e paa ai i ka pahikaua.
“Ọmọ ènìyàn, Èmi ti ṣẹ́ apá Farao ọba Ejibiti. A kò ì tí ì di apá náà papọ̀ láti mu kí ó san, a kò sì ti di i si àárín igi pẹlẹbẹ kí o lè ni agbára tó láti di idà mú.
22 Nolaila, ke i mai nei Iehova ka Haku, Eia hoi, ke ku e nei au ia Parao ke alii o Aigupita, a e uhai au i kona mau lima, i ka mea ikaika a me ka mea i uhaiia; a e hoohaule iho au i ka pahikaua mai loko iho o kona lima.
Nítorí náà, báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí: Èmi lòdì sí Farao ọba Ejibiti. Èmi yóò sẹ́ apá rẹ̀ méjèèjì, èyí tí ó dára àti èyí tí a ti ṣẹ́ pẹ̀lú, yóò sì mú kí idà bọ́ sọnù ní ọwọ́ rẹ̀.
23 A e hoopuehu au i ko Aigupita iwaena o na lahuikanaka, a e lulu aku ia lakou ma na aina.
Èmi yóò sì fọ́n àwọn ènìyàn Ejibiti ká sí àárín àwọn orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká gbogbo ilẹ̀.
24 A e hooikaika au i na lima o ke alii o Babulona, a e haawi i ka'u pahikaua iloko o kona lima; aka, e uhai au i na lima o Parao, a e auwe oia imua ona me ka auwe ana o ka mea eha e make ai.
Èmi yóò mú kí apá ọba Babeli ní agbára, èmi yóò sì fi idà mi sí ọwọ́ rẹ, ṣùgbọ́n èmi yóò ṣẹ́ apá Farao, yóò sì kérora níwájú rẹ̀ bí ọkùnrin tí a sá ní àṣápa.
25 Aka, e hooikaika au i na lima o ke alii o Babulona, a e haule na lima o Parao ilalo; a e ike lakou owau no Iehova, i ka wa e haawi aku ai au i ka'u pahikaua iloko o ka lima o ke alii o Babulona, a e o aku oia ia maluna o ka aina Aigupita.
Èmi yóò mú kí apá ọba Babeli lé, ṣùgbọ́n apá Farao yóò sì rọ. Nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa, nígbà tí mo bá mú idà mi sí ọwọ́ ọba Babeli yóò sì fi idà náà kọlu Ejibiti.
26 A e hoopuehu au i ko Aigupita iwaena o na lahuikanaka, a e lulu aku ia lakou ma na aina; a ike lakou owau no Iehova.
Èmi yóò fọ́n àwọn ara Ejibiti ká sí àárín orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sí àárín orílẹ̀-èdè, èmi yóò sì tú wọn ká sí gbogbo ilẹ̀. Nígbà náà wọn yóò mọ̀ pé èmi ni Olúwa.”

< Ezekiela 30 >