< Ezekiela 25 >

1 HIKI mai la ka olelo o Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mí wá wí pé:
2 E ke keiki a ke kanaka, e hoku e oe i kou maka i na mamo a Amona, a e wanana ku e ia lakou;
“Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí àwọn ará Ammoni kí ó sì sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí wọn.
3 A e olelo aku i na mamo a Amona, E hoolohe i ka olelo a Iehova ka Haku, Ke i mai nei Iehova ka Haku penei; No kau olelo ana, Aikola, no kuu keenakapu i kona wa i hoohaumiaia'i, a no ka aina o Iseraela i kona neoneo ana, a no ka ohana a Iuda i ko lakou hele pio ana;
Sì wí fún àwọn ará Ammoni pé, ‘Ẹ gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa Olódùmarè tí ó wí pé. Nítorí tí ìwọ wí pé, “Á hà!” Sí ibi mímọ́ mi nígbà tí ó di àìlọ́wọ̀ àti sí orí ilẹ̀ Israẹli nígbà tí ó di ahoro; àti sí ilẹ̀ Juda, nígbà tí wọ́n lọ sí ìgbèkùn,
4 Nolaila ea, e haawi aku au ia oukou i ka lima o ka poe hanauna no ka hikina, i waiwai no lakou, a e hoonoho lakou i ko lakou mau pa holoholona iloko ou, a e hana no lakou i ko lakou wahi e noho ai iloko ou; a e ai lakou i kau mau hua, a e inu lakou i kau waiu.
kíyèsi i, nítorí náà ni èmi yóò fi fi ọ lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn lọ́wọ́ ni ohun ìní. Wọn yóò sì gbé ààfin wọn kalẹ̀ nínú rẹ, wọn yóò sì gbé ibùgbé wọn nínú rẹ, wọn yóò jẹ èso rẹ, wọn yóò sì mu wàrà rẹ.
5 A e hoawi aku au ia Raba i hale hanai no na kamelo, a me na mamo a Amona i wahi e moe ai na ohana holoholona, a e ike oukou owau no Iehova.
Èmi yóò sì sọ Rabba di ibùjẹ, fún àwọn ìbákasẹ àti àwọn ọmọ Ammoni di ibùsùn fún agbo ẹran. Nígbà náà ni ẹ̀yin yóò mọ̀ pé, Èmi ni Olúwa.
6 No ka mea, ua pai oe i kou mau lima, a ua hehi hoi me na wawae, a ua hauoli hoi ma ka uhane, me kou hoowahawaha a pau, i ka aina o ka Iseraela;
Nítorí báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí. Nítorí pé ìwọ pàtẹ́wọ́, ìwọ sì jan ẹsẹ̀ mọ́lẹ̀, tí ìwọ ń yọ̀ pẹ̀lú gbogbo àrankàn rẹ sí ilẹ̀ Israẹli
7 Nolaila, ea, e kikoo aku au i kuu lima maluna ou, a e haawi aku au ia oe i na lahuikanaka i waiwai pio, a e oki aku au ia oe mai ka lahuikanaka aku, a e hoopau aku hoi au ia oe mailoko aku o na aina; a e luku au ia oe; a e ike oe owau no Iehova,
nítorí náà, èmi yóò na ọwọ́ mi lé ọ, èmi yóò sì fi ọ fún àwọn aláìkọlà fún ìkógun. Èmi yóò sì gé ọ kúrò láàrín àwọn ènìyàn, èmi yóò sì jẹ́ kí o parun kúrò ni ilẹ̀ gbogbo. Èmi yóò sì pa ọ́ run, ìwọ yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
8 Ke i mai nei Iehova ka Haku penei; No ka mea, ke olelo nei o Moaba, a me Seira, Ua like ka ohana a Iuda me na lahuikanaka a pau;
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí pé Moabu àti Seiri sọ wí pé, “Wò ó, ilé Juda ti dàbí gbogbo àwọn kèfèrí,”
9 Nolaila, ea, e wahi ae au i ka aoao o Moaba mai kona mau kulanakauhale ae, mai kona mau kulanakauhale ae ma kona mau kihi, ka mea nani o ka aina, o Betaiesimota, Baalameona, a me Kiriataima,
nítorí náà, Èmi yóò ṣí Moabu sílẹ̀ láti àwọn ìlú gbogbo tí ó wà ní ààlà rẹ̀, ògo ilẹ̀ náà, Beti-Jeṣimoti, Baali-Meoni àti Kiriataimu.
10 A me na mamo a Amona, e haawi au ia i hooilina no na kanaka o ka hikina i ole e hoomanao hou ia na mamo a Amona iwaena o na lahuikanaka.
Èmi yóò fi Moabu pẹ̀lú àwọn ará Ammoni lé àwọn ènìyàn ìlà-oòrùn ní ìní, kí a má bà á lè rántí àwọn ará Ammoni láàrín orílẹ̀-èdè gbogbo.
11 A e hoopai au maluna o Moaba; a e ike lakou, owau no Iehova,
Èmi yóò sì mú ìdájọ́ sẹ sí Moabu lára, wọn yóò sì mọ̀ pé èmi ni Olúwa.’”
12 Ke i mai nei Iehova ka Haku, No ka lawelawe ana o Edoma i ka hoopai ana i ka ohana a Iuda, a ua hana hewa loa, a ua hoopaiia lakou nona iho;
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí pé Edomu gbẹ̀san lára ilé Juda, ó sì jẹ̀bi gidigidi nípa ṣíṣe bẹ́ẹ̀,
13 Nolaila, ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; E kikoo aku au i kuu lima maluna o Edoma, a e oki aku i kanaka a me na holoholona mai ona aku la; a e hooneoneo aku ia mai Temana; a e haule i ka pahikaua ko Dedana.
nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé: Èmi yóò na ọwọ́ mi sórí Edomu èmi yóò sì pa àwọn ènìyàn àti àwọn ẹranko rẹ̀. Èmi yóò fi ṣófo láti Temani dé Dedani yóò ti ipa idà ṣubú.
14 A e kau aku au i kuu hoopai ana maluna o Edoma ma ka lima o kuu poe kanaka o Iseraela; a e hana aku lakou ia Edoma mamuli o ko'u huhu, a mamuli o ko'u ukiuki; a e ike lakou i ko'u hoopai ana, wahi a Iehova ka Haku.
Èmi yóò gbẹ̀san lára Edomu láti ọwọ́ àwọn ènìyàn mi Israẹli, wọn sì ṣe sí Edomu gẹ́gẹ́ bí ìbínú àti ìrunú mi, wọn yóò mọ̀ ìgbẹ̀san mi ní Olúwa Olódùmarè wí.’”
15 Ke i mai nei Iehova, ka Haku, penei; No ka hana ana o na Pilisetia ma ka hoopai ana, a ua hoopai lakou me ka naau hoomauhala, e luku ana mamuli o ka huhu kahiko;
“Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí pé: ‘Nítorí tí àwọn ará Filistini hùwà ẹ̀san tí wọ́n sì gbẹ̀san pẹ̀lú odì ní ọkàn wọn, àti pẹ̀lú ìkórìíra gbangba àtijọ́ ní wíwá ọ̀nà láti pa Juda run,
16 Nolaila, ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; Eia hoi, e kikoo aku au i kuu lima maluna o na Pilisetia, a e oki aku au i na Kereti, a e luku aku au i ke koena o ko kahakai.
nítorí náà báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí pé, “Èmi ti ṣetán láti na ọwọ́ mi jáde sí àwọn ará Filistini, èmi yóò sì ké àwọn ará Kereti kúrò, èmi yóò sì pa àwọn tí ó kù ní etí kún run.
17 A e hoopai nui au ia lakou, me ka papa huhu aku; a e ike no lakou owau no ka Haku i kuu wa e kau ai i ko'u hoopai ana maluna o lakou,
Èmi yóò sì gbẹ̀san ńlá lára wọn nípa ìbáwí gbígbóná; wọn yóò sì mọ̀ wí pé, Èmi ni Olúwa. Nígbà tí èmi yóò gba ẹ̀san lára wọn.”’”

< Ezekiela 25 >