< Ezekiela 21 >

1 A LAILA hiki mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
2 E ke keiki a ke kanaka, e hooku oe i kou wahi maka ia Ierusalema, a hoolei aku i kau olelo ma ke kupono i ua wahi hoano, a e wanana ku e i ka aina o ka Iseraela,
“Ọmọ ènìyàn, kọ ojú rẹ sí ìhà Jerusalẹmu, kí o sì wàásù lòdì sí ibi mímọ́. Sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí ilẹ̀ Israẹli.
3 A e olelo aku i ka aina o ka Iseraela, Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; Ke ka e nei au ia oe, a e unuhi ae au i kuu pahikaua mailoko ae o kona wahi, a e oki aku au mai ou aku nei i ka mea pono a me ka mea hewa.
Kí ó sì sọ fún un pe, ‘Èyí yìí ni Olúwa wí, Èmi lòdì sí ọ. Èmi yóò fa idà mi yọ kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀, Èmi yóò sì ké olódodo àti ènìyàn búburú kúrò ni àárín yín.
4 A no ko'u oki ana aku mai ou aku nei i ka mea pono a me ka mea hewa, nolaila e hele aku ko'u pahikaua maiioko aku o kona wahi e ku e i na io a pau, mai ke kukuluhema, a ke kukuluakau;
Nítorí pé, èmi yóò ké olódodo àti olùṣe búburú kúrò, idà mi yóò jáde láti inú àkọ̀ rẹ̀ lòdì sí gbogbo ènìyàn láti gúúsù títí dé àríwá.
5 I ike ka io a pau, ua unuhi ae wau o Iehova i kuu pahikaua mailoko ae o kona wahi; aole ia e hoi hou iho.
Nígbà náà gbogbo ènìyàn yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ti yọ idà mi kúrò nínú àkọ̀ rẹ̀; kì yóò sì padà sínú rẹ̀ mọ́.’
6 Nolaila e auwe oe, e ke keiki a ke kanaka, me ka hai ana o kou puhaka, a me ke kaumaha loa e auwe ai imua o ko lakou mau maka.
“Nítorí náà, mí ìmí ẹ̀dùn ìwọ ọmọ ènìyàn! Mí ìmí ẹ̀dùn pẹ̀lú ọkàn ìbànújẹ́ àti ẹ̀dùn ọkàn kíkorò ní iwájú wọn.
7 Eia hoi, i ko lakou ninau ana ia oe, No ke aha la oe e auwe nei? e olelo aku oe, No ka louo; no ka mea, e hiki mai ana no; a e hehee no na naau a pau, a e pau no na lima i ka nawaliwali, a e maule no hoi na kuli a pau me he wai la: no ka mea, eia hoi, e hele mai no ia, a e hookoia, wahi a Iehova ka Haku.
Bí wọ́n bá sì bi ọ́, wí pé, ‘Kí ni ó dé tí ìwọ fi ń mí ìmí ẹ̀dùn?’ Ìwọ yóò wí pé, ‘Nítorí ìròyìn tí ó ń bẹ. Gbogbo ọkàn ni yóò yọ́, gbogbo ọwọ́ ni yóò sì di aláìlera; gbogbo ọkàn ní yóò dákú, gbogbo eékún ni yóò sì di aláìlera bí omi?’ Ó ń bọ̀! Yóò sì wa sí ìmúṣẹ dandan, ni Olúwa Olódùmarè wí.”
8 Hiki hou mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa si tún tọ̀ mí wá pé:
9 E ke keiki a ke kanaka, e wanana aku oe, a e olelo aku, Ke i mai nei ka Haku penei; E ka pahikaua, ua hookalaia ka pahikaua, ua hoohualiia:
“Ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ wí pé, èyí yìí ní Olúwa wí pé, “‘Idà kan, idà kan, tí a pọ́n, tí a sì dán pẹ̀lú,
10 Ua hookalaia i luku nui aku ia; a ua hoohualiia ia e olinolino ia: he pono no anei ia kakou ke hana lealea? Ua hoowahawaha no ke kookoo o ka'u keiki i na kumu laau a pau.
a pọ́n láti pa ènìyàn púpọ̀, a dán an láti máa kọ mọ̀nà! “‘Àwa o ha máa ṣe àríyá ọ̀gọ ọmọ mi? Idà gán gbogbo irú igi bẹ́ẹ̀.
11 Ua haawiia mai no ia e hoohualiia ia i lawelaweia; ua hookalaia keia pahikaua, a ua hoohualiia e haawiia iloko o ka lima o ka mea luku.
“‘Idà ní a yàn láti pọ́n, kí ó lè ṣe é gbámú; a pọ́n ọn, a sì dán an, ó ṣetán fún ọwọ́ àwọn apani.
12 E auwe ae, a e aoa ae, e ke keiki a ke kanaka, no ka mea, maluna auanei ia o ko'u poe kanaka, maluna no ia o na'lii a pau o ka Iseraela; ua haawi pu ia lakou i ka pahikaua me ko'u poe kanaka; nolaila e hahau oe maluna iho o kou uha.
Sọkún síta, kí ó sì pohùnréré ẹ̀kún, ọmọ ènìyàn, nítorí yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi; yóò wá sórí gbogbo ọmọ-aládé Israẹli ìbẹ̀rù ńlá yóò wá sórí àwọn ènìyàn mi nítorí idà náà; nítorí náà lu oókan àyà rẹ.
13 No ka mea, ho hoao ana keia, a heaha la hoi ke hoowahawaha aku ia i ke kookoo? aole e koe aku ia, wahi a Iehova ka Haku.
“‘Ìdánwò yóò dé dandan. Tí ọ̀pá aládé Juda èyí tí idà kẹ́gàn, kò bá tẹ̀síwájú mọ́ ń kọ́? Ni Olúwa Olódùmarè wí.’
14 E wanana hoi oe, e ko keiki a ke kanaka, a e pai pu i kou mau lima, i ekolu hoi ka papalua ana o ka pahikaua, he pahikaua a ka poe i lukuia: o ka pahikaua ia a ka poe kanaka nui i pepehiia ka i hoopuni ia.
“Nítorí náà, ọmọ ènìyàn, sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì fi ọwọ́ lu ọwọ́. Jẹ́ kí idà lu ara wọn lẹ́ẹ̀méjì, kódà ní ẹ̀ẹ̀mẹta. Ó jẹ́ idà fún ìpànìyàn idà fún ìpànìyàn lọ́pọ̀lọ́pọ̀, tí yóò sé wọn mọ́ níhìn-ín àti lọ́hùnnún.
15 Ua hoonoho au i ka maka o ka pahikaua e ku e i ko lakou mau ipuka a pau i maule ka naau, a i hoonuiia ka hiolo ana: Auwe ua hoohualiia ia, ua unuhiia uo ka luku ana.
Kí ọkàn kí ó lè yọ́ kí àwọn tí ó ṣubú le pọ̀, mo ti gbé idà sí gbogbo bodè fún ìparun. Háà! A mú kí ó kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná, a gbá a mú fún ìparun.
16 E hui pu, e hele oe ma kekahi aoao, ma ka lima akau paha ma ka lima hema paha, ma kahi i ku pono ai kou alo.
Ìwọ idà, jà sí ọ̀tún kí o sì jà sí òsì lọ ibikíbi tí ẹnu rẹ bá dojúkọ.
17 Owau no kekahi e pai pu i ko'u mau lima, a e hoomaha au i ko'u ukiuki: na'u na Iehova i olelo iho.
Èmi gan an yóò pàtẹ́wọ́ ìbínú mi yóò sì rẹlẹ̀. Èmi Olúwa ti sọ̀rọ̀.”
18 Hiki hou mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ mi wá:
19 O oe hoi, e ke keiki a ke kanaka, e hoomaopopo oe i na ala elua, e hele mai ai ka pahikaua a ke alii o Babulona; e hele pu mai laua a elua mai ka aina hookahi mai; e koho oe i kekahi wahi, e koho ma ke poo o ke ala e hiki ai i ke kulanakauhale.
“Ọmọ ènìyàn la ọ̀nà méjì fún idà ọba Babeli láti gbà, kí méjèèjì bẹ̀rẹ̀ láti ìlú kan náà. Ṣe àmì sí ìkóríta ọ̀nà tí ó lọ sí ìlú náà.
20 Hoomaopopo i ke ala e hiki mai ai ka pahikaua i Raba no na mamo a Amona, a ia Iuda iloko o Ierusalema ka mea i paa i ka paia.
La ọ̀nà kan fún idà láti wá kọlu Rabba ti àwọn ará Ammoni kí òmíràn kọlu Juda, kí ó sì kọlu Jerusalẹmu ìlú olódi.
21 No ka mea, ua ku iho la ke alii o Babulona ma ka mahele ana o ke alanui, ma ke poo o na ala elua, e kilokilo ai; hoonaueue oia i kana mau pua, kukakuka no ia me na kii, ua nana no ia i ke akepaa.
Nítorí ọba Babeli yóò dúró ni ìyànà ní ojú ọ̀nà, ní ìkóríta, láti máa lo àfọ̀ṣẹ. Yóò fi ọfà di ìbò, yóò béèrè lọ́wọ́ àwọn òrìṣà rẹ̀, òun yóò ṣe àyẹ̀wò ẹ̀dọ̀.
22 Ma kona lima akau ke kilokilo ana no Ierusalema, e hoonoho ai i na hipa kane wawahi, e hoohamama i ka waha no ka luku ana, e hookiekie hoi i ka leo i ka hooho ana, e hoonoho ku e i na hipa kane wawahi ma na ipuka, e hookumu hoi i ka puu, a kukulu hoi i ka pakaua.
Nínú ọwọ́ ọ̀tún rẹ ni ìbò Jerusalẹmu yóò ti wá, ní ibi tí yóò ti gbé afárá kalẹ̀, láti pàṣẹ fún àwọn apànìyàn, láti mú ki wọn hó ìhó ogun láti gbé òòlù dí ẹnu-ọ̀nà ibodè, láti mọ odi, àti láti kọ́ ilé ìṣọ́.
23 E lilo hoi ia me he kilokilo wahahee ana i ko lakou maka, i na mea i hoohiki ai ma ka berita ia lakou; aka, e hoomanao oia i ka hewa e paa lakou i ka hopuia.
Àfọ̀ṣẹ náà yóò dàbí àmì èké sí àwọn tí ó ti búra ìtẹríba fún un, ṣùgbọ́n òun yóò ran wọn létí ẹbí wọn yóò sì mú wọn lọ sí ìgbèkùn.
24 Nolaila, ke i mai nei Iehova ka Haku penei; No ka mea, no oukou i hoomanaoia'i ko oukou hewa, i ka hoikeia o ko oukou lawehala ana, i ikeia hoi ka oukou hana ana a pau, no ko oukou hoomanaoia'e, e hopuia oe me ka lima.
“Nítorí náà èyí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí: ‘Nítorí ti ẹ̀yin ti mú ẹ̀bi yín wá sí ìrántí nípa ìṣọ̀tẹ̀ ní gbangba, ní ṣíṣe àfihàn àwọn ẹ̀ṣẹ̀ rẹ nínú gbogbo ohun tí ó ṣe, nítorí tí ẹ̀yin ti ṣe èyí, a yóò mú yín ní ìgbèkùn.
25 A o oe, e ke alii aia hewa o ka Iseraela, ua hiki mai kona la e oki ai ka hewa.
“‘Ìwọ aláìmọ́ àti ẹni búburú ọmọ-aládé Israẹli, ẹni ti ọjọ́ rẹ̀ ti dé, ẹni tí àsìkò ìjìyà rẹ̀ ti dé góńgó,
26 Ke i mai nei Iehova ka Haku, penei; E lawe oe i ka lei alii, a e hemo hoi ke korona: aole ia mea hookahi; e hookiekie ae i ka mea haahaa, a e hoohaahaa i ka mea kiekie.
èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí, tú ìwérí kúrò kí o sì gbé adé kúrò. Kò ní rí bí ti tẹ́lẹ̀, ẹni ìgbéga ni a yóò sì rẹ̀ sílẹ̀.
27 Na'u no e hookahuli, hookahuli, hookahuli ia mea; a e ole ia, a hiki mai ka mea ia ia ka pono, a e haawi au ia nona.
Ìparun! Ìparun! Èmi yóò ṣé e ni ìparun! Kì yóò padà bọ̀ sípò bí kò ṣe pé tí ó bá wá sí ọ̀dọ̀ ẹni tí ó ní ẹ̀tọ́ láti ni in; òun ni èmi yóò fi fún.’
28 A o oe, e ke keiki a ke kanaka, e wanana oe a e olelo aku no na mamo a Amona, a me ko lakou hoino, e olelo hoi oe, O ka pahikaua, na unuhiia ka pahikaua; ua hoohualiia no ka luku ana, e hoopau ai no kona olinolmo ana.
“Àti ìwọ, ọmọ ènìyàn sọtẹ́lẹ̀ kí ó sì wí pé, ‘Èyí yìí ní ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nípa àwọn ará Ammoni àti àbùkù wọn: “‘Idà kan idà kan tí á fa yọ fún ìpànìyàn tí a dán láti fi ènìyàn ṣòfò àti láti kọ bí ìmọ̀nàmọ́ná!
29 I ko lakou ike ana i ka mea hoopunipuni nou, a i ko lakou kilokilo ana i ka wahahee, e haawi ia oe maluna o na a-i o ka poe i pepehiia, o ka poe hewa, ua hiki mai ko lakou la e oki ai ko lakou hewa.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé a rí èké nípa yín àti àfọ̀ṣẹ èké nípa yín a yóò gbé e lé àwọn ọrùn ènìyàn búburú ti a ó pa, àwọn tí ọjọ́ wọn ti dé, àwọn tí ọjọ́ ìjìyà wọn ti dé góńgó.
30 E hoihoi anei au ia mea iloko o kona wahi? Ma kahi i hanaia'i oe, a ma ka aina i hanauia'i oe, malaila au e hoopai aku ai ia oe:
“‘Dá idà padà sínú àkọ̀ rẹ̀. Níbi tí a gbé ṣẹ̀dá yín, ní ibi tí ẹ̀yin ti ṣẹ̀ wá.
31 E ninini aku hoi au i kuu inaina maluua ou, a e puhi aku au ia oe me ke ahi o ko'u huhu ana, a e haawi aku au ia oe iloko o ka lima o na kanaka lokoino, a he akamai i ka luku aku.
Níbẹ̀ ni èmi yóò ti ṣe ìdájọ́ yín, èmi o sì fi èémí ìbínú gbígbóná mi bá yín jà.
32 E lilo no oe i wahie no ke ahi, mawaenakonu hoi o ka aina kou koko; aole hoi oe e hoomanao hou ia; no ka mea, na'u na Iehova ia i olelo ai.
Ẹ̀yin yóò jẹ́ èpò fún iná náà, a yóò ta ẹ̀jẹ̀ yin sórí ilẹ̀ yín, a kì yóò rántí yín mọ́; nítorí Èmi Olúwa ní ó ti wí bẹ́ẹ̀.’”

< Ezekiela 21 >