< Ezekiela 17 >

1 HIKI mai la ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ ní wá wí pé:
2 E ke keiki a ke kanaka, e nane aku oe i ka nane, a e olelo nane i ka ohana a Iseraela.
“Ọmọ ènìyàn pa àlọ́ kan, sì pa òwe kan fún ilé Israẹli.
3 A e olelo aku hoi ia lakou, Ke i mai nei Iehova ka Haku penei; He aeto nui, me na eheu nui loa, paapu i na hulu, onionio, hele mai ia i Lebanona, a lawe oia i ka lala kiekie loa o ka laau kedera.
Sọ fún wọn pé, ‘Báyìí ni Olúwa Olódùmarè wí, idì ńlá kan tó ní apá títóbi àti ìyẹ́ gígùn tó kún fún àwọ̀ oríṣìíríṣìí wa si Lebanoni, ó sì mu ẹ̀ka igi kedari tó ga jùlọ,
4 Ako ae la oia i ka welau o kona mau lala opiopio, a hali ae la ia i ka aina kalepa, hoonoho hoi ia i ke kulanakauhale o ka poe kalepa;
ó gé ọ̀mùnú orí ẹ̀ka yìí kúrò, ó mú un lọ sí ilẹ̀ oníṣòwò, ó sì gbìn ín sí ìlú àwọn oníṣòwò.
5 Lawe hoi oia i hua o ka aina, a kanu hoi ma ka mala hua nui; waiho iho la oia ia ma ka pili wai nui, hoonoho iho la ia me he laau wilou la.
“‘Ó mú lára irúgbìn ilẹ̀ náà, ó gbìn ín sí ilẹ̀ ọlọ́ràá, lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi, ó gbìn ín bí igi wílóò.
6 A ulu hoi ia a lilo ia i kumu waina palahalaha, he kino haahaa, huli ae ia kona mau lala mamuli ona, a malalo iho ona kona mau aa: a pela i lilo ia i kumu waina, a manamana ae la na lala, a opuu ae la na manamana.
Ó dàgbà, ó sì di àjàrà tó kúrú ṣùgbọ́n to bolẹ̀. Àwọn ẹ̀ka rẹ̀ kọjú sí i, gbòǹgbò rẹ̀ sì dúró lábẹ́ rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó di àjàrà, ó sì mu ẹ̀ka àti ewé jáde.
7 Aia hoi kekahi aeto nui me na eheu nui a me na hulu lehulehu; aia hoi, hoololi ae la keia kumu waina i kona mau aa io na la, a hoopuka ae la i kona mau lala io na la i hoopulu oia ia ia ma na kaha o kona mala.
“‘Ṣùgbọ́n ẹyẹ idì ńlá mìíràn tún wá, tó ní apá títóbi pẹ̀lú ìyẹ́ púpọ̀. Gbòǹgbò àjàrà náà sì ta lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ láti orí ilẹ̀ tí wọn gbìn ín sí, ó wá pẹ̀ka lọ sọ́dọ̀ rẹ̀ kí ó le fún un ni omi.
8 Ua kanuia ma ka lepo maikai ma na wai nui; i haawi mai ai ia i na lala, a i hoohua mai ai i ka hua; a i lilo ai ia i kumu waina maikai.
Orí ilẹ̀ tó dára lẹ́gbẹ̀ẹ́ ọ̀pọ̀lọpọ̀ omi ni a gbìn ín sí, kí ó bá à le pẹ̀ka, kò sì so èso, ó sì wá di igi àjàrà tó lọ́lá púpọ̀.’
9 E olelo oe, Ke i mai nei Iehova ka Haku; E pomaikai anei? Aole anei e uhuki oia i kona mau aa, a e oki aku i kona mau hua, i mae iho ai ia? E mae auanei no ia ma na lau a pau o kona ulu ana'e, aole me ka mana nui, aole hoi me kanaka he nui e uhuki ai ia me na aa ona.
“Sọ fún wọn pé, ‘Ohun tí Olúwa Olódùmarè wí nìyí, yóò wá gbilẹ̀ bí? A kò wá ní i wú gbòǹgbò rẹ̀, ki a si gé èso rẹ̀ kúrò kí ó bá à le rọ? Gbogbo ewé rẹ̀ tó ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ ni yóò rẹ̀. Kò sì nígbà agbára tàbí ènìyàn púpọ̀ láti fà gbòǹgbò rẹ̀ tu.
10 Aia hoi, i kanuia, e pomaikai anei ia? Aole anei ia e mae loa, i ka wa e pa mai ai ka makani hikina ia ia? E mae no ia iloko o na kaha i ulu ai ia.
Bí a tilẹ̀ tún un gbìn, yóò wa gbilẹ̀ bí? Kò wá ní i rọ pátápátá nígbà ti afẹ́fẹ́ láti ìlà-oòrùn bá kọlù ú. Gbogbo ewé rẹ̀ yóò rẹ̀ lórí ilẹ̀ tó ti dàgbà?’”
11 Hiki mai la no hoi ka olelo a Iehova ia'u, i mai la,
Nígbà náà, ni ọ̀rọ̀ Olúwa tọ̀ mi wá pé:
12 E olelo, ano, i ka ohana kipi, Aole anei oukou i ike i ke ano o keia mau mea? E olelo aku hoi, Eia hoi, ua hiki mai ke alii o Babulona i Ierusalema, a ua lawe oia i kona alii a me na'lii ona, a ua alakai ia lakou me ia i Babulona;
“Sọ fún ọlọ̀tẹ̀ ilé yìí, ‘Ǹjẹ́ ẹ mọ ìtumọ̀ àwọn nǹkan wọ̀nyí?’ Sọ fún wọn: ‘Ọba Babeli wá sí Jerusalẹmu, ó sì kó ọba àti àwọn ìjòyè ọmọ-aládé ibẹ̀ lọ sí Babeli lọ́dọ̀ rẹ̀.
13 A ua lawe oia i kekahi o ka poe keiki alii, a kuikahi pu ae la oia me ia; a ua lawe oia i kona hoohiki ana ma ke kuikahi; ua lawe aku hoi oia i ka poe ikaika o ka aina;
Lẹ́yìn èyí, ó bá ọ̀kan nínú ọmọ ọba dá májẹ̀mú, ó mú un ìbúra, ó tún kó àwọn alágbára ilẹ̀ náà lọ.
14 I haahaa ai ke aupuni, aole hoi e hiki ke ea'e iluna, aka, ma kona malama ana i kona kuikahi e mau ai ia.
Kí ìjọba ilẹ̀ náà le rẹ ilẹ̀, kí ó má lè gbé ara rẹ̀ sókè, kí ó lè dúró nípa pípa májẹ̀mú rẹ̀ mọ́.
15 Ua kipi nae oia ia ia i kona hoouna ana i na elele i Aigupita, i haawi mai lakou i na lio, a i kanaka he nui no. E pomaikai anei oia? E pakele anei ka mea hana ia mau mea? A, e uhai paha oia i ke kuikahi a e hoopakeleia anei?
Ṣùgbọ́n ọba ṣọ̀tẹ̀ sí i nípa ríran àwọn ikọ̀ rẹ̀ lọ sí Ejibiti, kí wọn bá à lè fún un ni ẹṣin àti àwọn ọmọ-ogun púpọ̀. Yóò ha ṣe àṣeyọrí? Ṣe ẹni tó ṣe irú nǹkan yìí yóò sì bọ́ níbẹ̀? Yóò ha dalẹ̀ tán kí ó sì bọ́ níbẹ̀ bí?
16 Ma ko'u ola ana, wahi a Iehova ka Haku, he oiaio, ma kahi o ke alii ka mea i hoolilo ia ia i alii, ka mea nona ka hoohiki ana ana i hoowahawaha ai, a o kona berita hoi kana i uhai aku ai, me ia mawaenakonu o Babulona e make ai ia.
“‘Bí mo ti wà láààyè ni Olúwa Olódùmarè wí, òun yóò kú ní Babeli, ní ilẹ̀ ọba tó fi sórí oyè, ìbúra ẹni tí ó kẹ́gàn àti májẹ̀mú ẹni tí ó dà.
17 Aole hoi o Parao me kona poe kaua mana, a me kona anaina nui e kokua ia ia i ke kaua, ma ka hana ana i na puu, a me na pakaua, e oki aku ai i na kanaka he nui;
Farao pẹ̀lú àwọn ọmọ-ogun àti àjọ ńlá rẹ̀ kò ní lè ṣe ìrànwọ́ fún un lójú ogun. Nígbà tí wọ́n bá pa bùdó ogun tì í, tí wọ́n sì mọ odi láti pa ọ̀pọ̀ ènìyàn.
18 I kona hoowahawaha ana i ka hoohiki ana, ma ka uhai ana i ke kuikahi, i ka wa i haawi ai oia i kona lima, a ua hana hoi oia i keia mau mea a pau, aole ia e pakele.
Nítorí pé ó kẹ́gàn ìbúra nípa dída májẹ̀mú, àti pé ó juwọ́ sílẹ̀ nínú ṣíṣe ìlérí, kì yóò bọ níbẹ̀ pẹ̀lú gbogbo àwọn nǹkan tí ó ṣe yìí.
19 Nolaila ke i mai nei Iehova ka Haku penei; Ma ko'u ola ana, oiaio, o ka hoohiki ana no'u, ana i hoowahawaha ai, a me ko'u kuikahi ana i uhai aku ai, oia ka'u e hoopai ai maluna o kona poo.
“‘Nítorí náà Olúwa Olódùmarè wí pé, bí mo ti wà láààyè, Èmi yóò mú ẹ̀san ẹ̀jẹ́ mi tó kẹ́gàn àti májẹ̀mú mi tó dà wa sórí rẹ̀.
20 A e hohola au i ka'u upena maluna ona, a e hei oia i ka'u pahele; a e lawe au ia ia ma Babulona, a e hakaka au me ia ilaila, no kona hewa ana i hana hewa mai ai ia'u.
Èmi yóò ta àwọ̀n mi sórí rẹ̀, yóò sì bọ sínú okùn mi, Èmi yóò mú ọ lọ Babeli láti ṣe ìdájọ́ ìwà ọ̀dàlẹ̀ tó hù sí mi.
21 A e pau kona poe auhee me ka puali ona i ka haule i ka pahikaua, a o ka poe koe, e hele liilii lakou i kela makani keia makani; a e ike oukou na'u na Iehova i olelo aku.
Gbogbo ìgbèkùn àti ọ̀wọ́ ọmọ-ogun rẹ̀ ni yóò kú pẹ̀lú idà, èmi yóò sì fọn àwọn ìyókù ká sínú afẹ́fẹ́ káàkiri. Nígbà náà ni yóò mọ̀ pé, “Èmi Olúwa ni ó ti sọ̀rọ̀.”
22 Ke i mai nei o Iehova ka Haku penei; Owau no kekahi e lawe i ko ka lala kiekie loa o ka laau kedera kiekie, a e hoonoho iho au ia mea; e ako hoi au mai luna mai o kona mau lala opiopio i kekahi mea palupalu, a e kanu au ia mea maluna o ka mauna kiekie i hookiekieia.
“‘Báyìí ní Olúwa Olódùmarè wí, Èmi fúnra mi yóò mú ọ̀kan lára ẹ̀ka tí ó ga jùlọ lórí igi kedari gíga, tí èmi yóò sì gbìn ín, èmi yóò sì gé ọ̀mùnú tí ó ṣẹ̀ṣẹ̀ yọ láti òkè, èmi yóò sì gbìn ín sórí òkè tó ga tó sì lókìkí.
23 Ma ka mauna kiekie o ka Iseraela e kanu iho ai au ia, a e haawi mai ia i na lala a me ka hua, a e lilo ia i kumu kedera maikai; a malalo iho ona e noho ai na manu a pau ma kela eheu keia eheu: ma ka mala o kona mau lala e noho iho ai lakou.
Ní ibi gíga òkè Israẹli ni èmi yóò gbìn ín sí; yóò pẹ̀ka, yóò sì so èso, yóò wa di igi kedari tí ó lọ́lá. Oríṣìíríṣìí ẹyẹ yóò sì fi òjìji abẹ ẹ̀ka rẹ ṣe ibùgbé; wọn yóò ṣe ibùgbé si abẹ́ òjìji ẹ̀ka rẹ̀.
24 A e ike na laau a pau o ka aina, na'u na Iehova i hoohaahaa i ka laau kiekie, a i hookiekie hoi i ka laau haahaa, a i hoomaloo i ka laau uliuli, a i hooulu ae i ka laau maloo: na'u na Iehova i olelo, a i hana aku hoi.
Gbogbo igi inú oko yóò mọ̀ pé, Èmi Olúwa ni ó mú igi gíga walẹ̀, tí mo sì mú kúkúrú ga sókè, tí mo mu igi tútù gbẹ, tí mo sì mú igi gbígbẹ rúwé. “‘Èmi Olúwa ni ó sọ bẹ́ẹ̀, Èmi yóò sì ṣe e.’”

< Ezekiela 17 >