< Pukaana 20 >
1 OLELO mai la ke Akua i keia mau olelo a pau, i mai la.
Ọlọ́run sì sọ gbogbo ọ̀rọ̀ yìí pé,
2 Owau no Iehova o kou Akua, ka mea nana oe i lawe mai nei, mai ka aina o Aigupita mai, mailoko mai hoi o ka hale hooluhi.
“Èmi ni Olúwa Ọlọ́run yín, tí ó mú un yín jáde láti ilẹ̀ Ejibiti, láti oko ẹrú jáde wá.
3 Aole ou akua e ae imua o ko'u alo.
“Ìwọ kò gbọdọ̀ ní ọlọ́run mìíràn pẹ̀lú mi.
4 Mai hana oe i ke kii i kalaiia nou, aole ma ka like ana o kekahi mea i ka lani iluna, a me ko ka honua ilalo, a maloko hoi o ka wai malalo o ka honua:
Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ère fún ara yín, tàbí àwòrán ohun kan tí ń bẹ ní òkè ọ̀run, tàbí ti ohun kan tí ń bẹ ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀, tàbí ti ohun kan tí ń bẹ nínú omi ní ìsàlẹ̀ ilẹ̀.
5 Mai kulou oe ilalo ia lakou, aole hoi e hoomana ia lakou; no ka mea, owau no Iehova o kou Akua, he Akua lili; e hoopai ana i ka na makua hala i na keiki, a hiki aku i ke kuakahi a me ke kualua o ka poe e inaina mai ia'u:
Ìwọ kò gbọdọ̀ tẹ orí ara rẹ ba fún wọn, bẹ́ẹ̀ ni ìwọ kò gbọdọ̀ sìn wọ́n; nítorí Èmi Olúwa Ọlọ́run rẹ, Ọlọ́run owú ni mí, tí ń bẹ ẹ̀ṣẹ̀ àwọn baba wò lára àwọn ọmọ, láti ìran kẹta títí dé ẹ̀kẹrin nínú àwọn tí ó kórìíra mi.
6 A e aloha ana hoi i na tausani o ka, poe e aloha mai ia'u, a e malama hoi i ko'u mau kanawai.
Èmi a sì máa fi àánú hàn sí ẹgbẹẹgbẹ̀rún àwọn tí ó fẹ́ mi, tí wọ́n sì ń pa òfin mi mọ́.
7 Mai hoohiki wahahee oe i ka inoa o Iehova o kou Akua; no ka mea, aole loa e hoapono o Iehova i ka mea hoohiki wahahee i kona inoa.
Ẹ má ṣe ṣi orúkọ Olúwa Ọlọ́run yín lò, torí pé ẹnikẹ́ni tí o bá ṣi orúkọ rẹ̀ lò kì yóò lọ láìjẹ̀bi.
8 E hoomanao i ka la sabati, a e hoano ia.
Rántí ọjọ́ ìsinmi láti yà á sí mímọ́.
9 I na la eono e hana'i oe i kau haua a pau;
Ọjọ́ mẹ́fà ni ìwọ yóò fi ṣiṣẹ́, kí ìwọ kí ó ṣe gbogbo iṣẹ́ rẹ,
10 Aka, o ka hiku o ka la, he sabati ia no Iehova no kou Akua, aole loa oe e hana ia la, aole oe, aole hoi kou keikikane, aole hoi kou kaikamahine, aole hoi kau kauwakane, aole hoi kau kauwawahine, aole hoi kou holoholona, aole hoi kou kanaka e ma kou mau ipuka:
ṣùgbọ́n ọjọ́ keje ni ọjọ́ ìsinmi Olúwa Ọlọ́run rẹ: nínú rẹ̀ ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe iṣẹ́kíṣẹ́ kan: ìwọ, àti ọmọ rẹ ọkùnrin àti ọmọ rẹ obìnrin, ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ ọkùnrin àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ obìnrin, àti ẹran ọ̀sìn rẹ, àti àlejò rẹ, tí ń bẹ nínú ibodè rẹ.
11 No ka mea, i na la eono i hana'i o Iehova i na lani, a me ka honua, a me ke kai, a me na mea a pau maloko o ia mau mea, a i ka iku o ka la i hoomaha'i; nolaila hoi i hoomaikai ai o Iehova i ka la sabati, a hoano ai hoi oia ia la.
Nítorí ní ọjọ́ mẹ́fà ni Olúwa dá ọ̀run àti ayé, òkun àti ohun gbogbo tí ń bẹ nínú wọn, ó sì sinmi ní ọjọ́ keje: nítorí náà ni Olúwa ṣe bùkún ọjọ́ ìsinmi tí ó sì yà á sí mímọ́.
12 E hoomaikai oe i kou makuakane, a me kou makuwahine; i loihi ai kou mau la maluna o ka aina a Iehova a kou Akua i haawi mai ai ia oe.
Bọ̀wọ̀ fún baba òun ìyá rẹ, kí ọjọ́ rẹ kí ó lè pẹ́ ní orí ilẹ̀ tí Olúwa Ọlọ́run rẹ fi fún ọ.
Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe panṣágà.
16 Mai hoike hoopunipuni oe e hewa ai kou hoalauna.
Ìwọ kò gbọdọ̀ jẹ́rìí èké sí ẹnìkejì rẹ.
17 Mai kuko oe i ka hale o kou hoalauna, mai kuko i ka wahine a kou hoalauna, aole hoi i kana kauwakane, aole hoi i kana kauwawahine, aole hoi i kona bipi, aole hoi i kona hold, aole hoi i kekahi mea a kou hoalauna.
Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí ilé ẹnìkéjì rẹ. Ìwọ kò gbọdọ̀ ṣe ojúkòkòrò sí aya ẹnìkéjì rẹ, ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ ọkùnrin àti ọmọ ọ̀dọ̀ rẹ̀ obìnrin, akọ màlúù rẹ̀ àti kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́ rẹ̀ àti ohun gbogbo tí í ṣe ti ẹnìkéjì rẹ.”
18 Ike aku la na kanaka a pau i ke hekili, a me ka uila, a me ke kani ana o ka pu, a me ka mauna e uwahi ana: a ike aku la na kanaka, weliweli iho la; neenee aku la, a ku ma kahi mamao aku.
Nígbà tí àwọn ènìyàn náà rí mọ̀nàmọ́ná tí wọ́n sí gbọ́ ohùn ìpè àti èéfín tí ń rú láti orí òkè, tí wọ́n sì gbọ́ sísán àrá, dídún ìpè kíkankíkan; wọ́n dúró ní òkèrè wọ́n sì ń gbọ̀n ṣìgàṣìgà fún ìbẹ̀rù.
19 I aku la lakou ia Mose, Nau no makou e olelo mai, a e hoolohe aku no makou: aka, mai olelo mai ke Akua ia makou, o make auanei makou.
Wọ́n wí fún Mose pé, “Ìwọ fúnra rẹ̀ máa bá wa sọ̀rọ̀, àwa yóò sì gbọ́. Má ṣe jẹ́ kí Ọlọ́run fúnra rẹ̀ kí ó bá wa sọ̀rọ̀, bí bẹ́ẹ̀ kọ́, àwa yóò kú.”
20 I aku la o Mose i kanaka, Mai weliweli oukou; no ka mea, ua hele mai ke Akua e hoao ia oukou, i mau kona makauia maluna o oukou, i lawehala ole oukou.
Mose sì sọ fún àwọn ènìyàn náà pé, “Ẹ má bẹ̀rù. Ọlọ́run wá láti dán an yín wò, kí ẹ̀rù Ọlọ́run kí ó lè máa wà ní ara yín, kí ẹ̀yin kí ó má ṣe ṣẹ̀.”
21 Ku mai la na kanaka ma kahi loihi e aku, a hookokoke aku la o Mose, i ke ao panopano a ke Akua i uoho ai.
Àwọn ènìyàn sì dúró ní òkèèrè nígbà tí Mose súnmọ́ ibi òkùnkùn biribiri níbi tí Ọlọ́run wà.
22 I mai la o Iehova ia Mose, E olelo aku oe i na mamo a Iseraela penei, Ua ike oukou i ka'u olelo ana ia oukou, mai ka lani mai.
Olúwa sì sọ fún Mose pé, “Sọ àwọn nǹkan wọ̀nyí fún àwọn ará Israẹli, ‘Ẹ̀yin ti rí i fúnra yín bí èmi ti bá a yín sọ̀rọ̀ láti ọ̀run wá.
23 Mai hana oe i na akua e me a'u nei i na akua kala, a mai hana i na akua gula no oukou.
Ẹ̀yin kò gbọdọ̀ sin ọlọ́run mìíràn pẹ̀lú mi: ẹ̀yin kò gbọdọ̀ rọ ọlọ́run fàdákà tàbí ọlọ́run wúrà fún ara yín.
24 E hana oe i kuahu lepo no'u a e mohai mai maluna iho i kou mohaikuni, a me kou mohai hoomalu, i kou mau hipa, a me kou mau bipi; i na wahi a pau a'u e hoopaa ai i ko'u inoa, mataila au e hele aku ai i ou la, a e hoomaikai ai ia oe.
“‘Pẹpẹ erùpẹ̀ ni kí ìwọ mọ fún mi. Ní orí pẹpẹ yìí ni kí ìwọ ti máa rú ẹbọ sísun rẹ sí mi àti ẹbọ àlàáfíà rẹ, àgùntàn rẹ, ewúrẹ́ àti akọ màlúù rẹ. Ní ibi gbogbo tí mo gbé fi ìrántí orúkọ mi sí, èmi yóò sì máa tọ̀ ọ́ wá, èmi yóò sì máa bùkún ọ níbẹ̀.
25 A i hana oe i kuahu pohaku, ea, mai hana oe i pohaku i kalaiia; no ka mea, ina e kau oe i kou koilipi maluna iho, ua haumia ia ia oe.
Bí ìwọ bá ṣe pẹpẹ òkúta fún mi, má ṣe fi òkúta tí a ṣe lọ́ṣọ̀ọ́ kọ́ ọ, nítorí bí ìwọ bá lo ohun ọnà rẹ lórí rẹ̀, ìwọ sọ ọ di àìmọ́.
26 Mai pii oe maluna o ko'u kuahu ma ke ala hanuu, o ikea aku kou wahi huna malaila.
Ìwọ kò gbọdọ̀ gun àkàsọ̀ lọ sí ibi pẹpẹ mi, kí àwọn ènìyàn má ba à máa wo ìhòhò rẹ láti abẹ́ aṣọ tí ìwọ wọ̀ nígbà tí ìwọ bá ń gòkè lọ sí ibi pẹpẹ.’