< Amosa 7 >

1 PENEIA i hoike mai ai o Iehova ka Haku ia'u: Aia hoi, hana iho la ia i na uhini i ka ulu mua ana o ka weuweu hope; aia hoi, o ka weuweu lua ia mahope o ka ke alii oki ana. A i ka wa i hoopau ai lakou i ka ai ana i ka weuweu o ka aina, alaila i aku la au,
Èyí ni ohun tí Olúwa Olódùmarè fihàn mí: Ó pèsè ọwọ́ eṣú lẹ́yìn ìgbà tí a kórè ìpín ọba, ní ìgbà ti èso ẹ̀ẹ̀kejì ń jáde bọ̀.
2 E Iehova ka Haku, ke noi aku nei au, e kala mai oe. Pehea la e ku mai ai o Iakoba? No ka mea, ua uuku ia.
Nígbà tí wọ́n jẹ koríko ilẹ̀ náà mọ́ féfé nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè pé, “Olúwa Olódùmarè, mo bẹ̀ ọ́, dáríjì! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe lè dìde? Òun kéré jọjọ!”
3 Huli ae la o Iehova no keia mea: aole ia e hiki mai, wahi a Iehova.
Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí. “Èyí kò ni ṣẹlẹ̀,” ni Olúwa wí.
4 Peneia i hoike mai ai o Iehova ka Haku ia'u; Aia hoi, kahea mai o Iehova ka Haku, e hakaka me ke ahi, a ai iho la ia i ka hohonunui, a hoopau iho la i kauwahi. Alaila, i aku la au,
Èyí ni ohun ti Olúwa Olódùmarè fihàn mí: Olúwa Olódùmarè ń pè fún ìdájọ́ pẹ̀lú iná; ó jó ọ̀gbun ńlá rún, ó sì jẹ ilẹ̀ run.
5 E ka Haku, e Iehova, ke noi aku nei au, e oki: Pehea e ku mai ai o Iakoba? No ka mea, ua uuku ia.
Nígbà náà ni mo gbé ohùn mi sókè pé, “Olúwa Olódùmarè jọ̀wọ́ má ṣe ṣe é! Báwo ni Jakọbu yóò ha ṣe lè dìde? Òun kéré jọjọ!”
6 Huli ae la o Iehova no keia mea: aole e hiki mai keia, wahi a Iehova ka Haku.
Olúwa ronúpìwàdà nípa èyí. “Èyí náà kò ní ṣẹlẹ̀,” ni Olúwa Olódùmarè wí.
7 Peneia i hoike mai ai oia ia'u: Aia hoi, ku mai la ka Haku maluna o ka papohaku kupono, me ka mea hookupono ma kona lima.
Èyí ni ohun tí ó fihàn mí: Olúwa dúró ní ẹ̀gbẹ́ odi ti a fi okùn ìwọ̀n mọ́, ti òun ti okùn ìwọ̀n tí ó rún ni ọwọ́ rẹ̀.
8 A i mai la o Iehova ia'u, E Amosa, heaha la kau e ike nei? A i aku la au, He mea hookupono. Alaila, i mai la o Iehova. Aia hoi, e hoonoho aku au i na mea hookupono iwaena o kuu poe kanaka o ka Iseraela: Aole au i hele hou ae mai o lakou aku.
Olúwa sì bi mi pé, “Amosi, kí ni ìwọ rí?” Mo dáhùn pé, “Okùn ìwọ̀n.” Nígbà náà ni Olúwa wí pé, “Wò ó, Èmí ń gbé okùn ìwọ̀n kalẹ̀ láàrín àwọn Israẹli ènìyàn mi; Èmi kì yóò sì tún kọjá lọ́dọ̀ wọn mọ́.
9 A e hooneoneoia na wahi kiekie o Isaaka, A e wawahiia na wahi hoano o ka Iseraela: A e ku e aku au i ka hale o Ieroboama me ka pahikaua.
“Ibi gíga Isaaki wọ̀n-ọn-nì yóò sì di ahoro àti ibi mímọ Israẹli wọ̀n-ọn-nì yóò di ahoro. Èmi yóò sì fi idà dìde sí ilé Jeroboamu.”
10 Alaila, hoouna aku la o Amazia, ke kahuna o Betela. Io Ieroboama la, ke alii o ka Iseraela, i aku la, Ua ku e mai o Amosa ia oe iwaena o ko ka hale o Iseraela: aole e hiki i ka aina ke hoomanawanui i kana mau olelo a pau.
Nígbà náà Amasiah àlùfáà Beteli ránṣẹ́ sí Jeroboamu ọba Israẹli, wí pé: “Amosi ti dìde láti dìtẹ̀ sí ọ ni àárín gbùngbùn Israẹli. Ilẹ̀ kò sì le gba gbogbo ọ̀rọ̀ rẹ̀.
11 No ka mea, ke olelo mai nei o Amosa penei, E make auanei o Ieroboama i ka pahikaua, a e lawe pio ia'ku ka Iseraela mai ko lakou aina aku.
Nítorí èyí ni ohun ti Amosi ń sọ: “‘Jeroboamu yóò ti ipa idà kú, lóòtítọ́ Israẹli yóò lọ sí ìgbèkùn, jìnnà kúrò ní ilẹ̀ ìní wọn.’”
12 Olelo aku la hoi o Amazia ia Amosa, E ke kaula ike, o hele, e holo aku oe i ka aina o Iuda, a malaila e ai ai i ka berena, a e wanana malaila:
Nígbà náà ni Amasiah sọ fún Amosi pé, “Lọ jáde, ìwọ aríran! Padà sí ilẹ̀ àwọn Juda. Kí o máa jẹun rẹ níbẹ̀, kí o sì máa sọtẹ́lẹ̀ rẹ̀ níbẹ̀.
13 A mai wanana hou ma Betela: no ka mea, he heiau keia no ke alii, a o ko ke alii hale noho keia.
Má ṣe sọtẹ́lẹ̀ mọ ni Beteli nítorí ibi mímọ́ ọba ni àti ibi tẹmpili ìjọba rẹ̀.”
14 Alaila, olelo aku la o Amosa, a i aku la ia Amazia, Aole wau he kaula mamua. aole hoi he keiki a ke kaula; aka, he hanai bipi wau, a he mea hoiliili hua sukamore:
Amosi dá Amasiah lóhùn pé, “Èmi kì í ṣe wòlíì tàbí àwọn ọmọ wòlíì, ṣùgbọ́n mo jẹ́ olùṣọ́-àgùntàn, mo sì ń ṣe ìtọ́jú igi ọ̀pọ̀tọ́ sikamore.
15 A lawe o Iehova ia'u mai ka hahai ana i na holoholona, a olelo mai o Iehova ia'u, E hele, e wanana aku i kuu poe kanaka i ka Iseraela.
Ṣùgbọ́n Olúwa mu mi bí mo ti ń tọ́ agbo ẹran lẹ́yìn, ó sì wí fun mi pé, ‘Lọ sọtẹ́lẹ̀ fun àwọn Israẹli ènìyàn mi.’
16 Ano hoi, e hoolohe oe i ka olelo a Iehova; Ke olelo nei oe, Mai wanana ku e aku i ka Iseraela, a mai hapai ku e oe i kau olelo i ko ka hale o Isaaka.
Nítorí náà nísinsin yìí, gbọ́ ọ̀rọ̀ Olúwa. Ìwọ wí pé, “‘Má ṣe sọ àsọtẹ́lẹ̀ sí Israẹli, má sì ṣe wàásù sí ilé Isaaki.’
17 No ia mea, ke olelo mai nei o Iehova, penei: E moe kolohe kau wahine ma ke kulanakauhale, a o kau mau keikikane, a me kau mau kaikamahine, e haule lakou i ka pahikaua, A e puunaueia kou aina me ke kaula-ana: a e make oe ma ka aina haumia; A e hele pio aku ka Iseraela mai ko lakou aina aku.
“Nítorí náà, èyí ni ohun ti Olúwa wí: “‘Ìyàwó rẹ yóò di panṣágà ni ìlú, àwọn ọmọ ọkùnrin àti obìnrin rẹ yóò ti ipa idà ṣubú. A ó fi okùn wọn ilẹ̀ rẹ, a ó sì pín in àti ìwọ pẹ̀lú yóò kú ni ilẹ̀ àìmọ́. Israẹli yóò sì lọ sí ìgbèkùn, kúrò ní ilẹ̀ ìní wọn.’”

< Amosa 7 >