< II Na Lii 8 >

1 A LAILA olelo aku la o Elisai i ka wahine, i ka mea nana ke keiki ana i hoola ai, i aku la, E ku ae, a hele aku, o oe, a me kau ohana, a noho ma kahi au e hiki ai ke noho: no ka mea, ua hai mai o Iehova, he wi, a e hiki mai no ia maluna o ka aina i na makahiki ehiku.
Nísinsin yìí, Eliṣa wí fún obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin jí padà sáyé pé, “Jáde lọ pẹ̀lú ìdílé rẹ kí o sì lọ dúró fún ìgbà díẹ̀ ní ibikíbi tí o bá le dúró sí, nítorí Olúwa ti pàṣẹ ìyàn ní ìlú tí yóò lò tó ọdún méje.”
2 Ku ae la ka wahine, a hana aku la e like me ka olelo a ke kanaka o ke Akua; a hele aku ia me kona ohua, a noho iho la ma ka aina o ko Pilisetia i na makahiki ehiku.
Obìnrin náà tẹ̀síwájú gẹ́gẹ́ bí ọ̀rọ̀ ènìyàn Ọlọ́run ti sọ. Òun àti ìdílé rẹ̀ sí lọ, wọ́n sì ṣe àtìpó ní ilẹ̀ àwọn ará Filistini fún ọdún méje.
3 A i ka pau ana o na makahiki ehiku, hoi mai la ka wahine mai ka aina o ko Pilisetia mai; a hele e no noi aku i ke alii no kona hale, a no kona aina.
Ní ẹ̀yìn ọdún méje ó sì padà wá láti ilẹ̀ àwọn ará Filistini ó sì lọ sí ọ̀dọ̀ ọba láti lọ bẹ̀ ẹ́ fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀.
4 A kamailio ae la ke alii me Gehazi ke kauwa a ke kanaka o ke Akua, i aku la, E helu mai oe ia'u i na hana mana a pau a Elisai i hana'i.
Ọba sì ń sọ̀rọ̀ sí Gehasi, ìránṣẹ́ ènìyàn Ọlọ́run pé, “Sọ fún mi nípa gbogbo ohun ńlá tí Eliṣa ti ṣe.”
5 A i ka manawa ana i hai aku ai i ke alii i kona hoola ana i ka mea i make, aia hoi, o ka wahine, nana ke keiki ana i hoola'i, nonoi mai la i ke alii no kona ohua, a no kona aina. I aku la o Gehazi, E ku a haku, e ke alii, o keia ka wahine, o keia hoi ke keiki a Elisai i hoola'i.
Bí Gehasi ti ń sọ bí tí Eliṣa ṣe jí òkú di alààyè, obìnrin náà tí ọmọ rẹ̀ ọkùnrin tí Eliṣa ti dá padà sí ayé wá láti bẹ ọba fún ilé àti ilẹ̀ rẹ̀. Gehasi sì wí pé, “Obìnrin náà nìyìí olúwa mi ọba, ọmọkùnrin rẹ náà nìyí tí Eliṣa ti jí dìde sí ayé.”
6 Ninau aku la ke alii i ka wahine, a hai mai kela ia ia. A kauoha aku la ke alii i kekahi luna i poaia nona, i aku la, E hoihoi aku i kana mea a pau, a i na hua a pau o ka aina, mai ka manawa ana i haalele ai i ka aina a hiki i keia wa.
Ọba béèrè lọ́wọ́ obìnrin náà nípa rẹ̀, ó sì sọ fún un. Ó sì yan ìjòyè kan fún ún fún ọ̀rọ̀ rẹ̀ ó sì wí fún un pé, “Ẹ fún un padà gbogbo ohun tí ó bá jẹ́ tirẹ̀, àti pẹ̀lú gbogbo èrè ilé rẹ̀ fún ún láti ọjọ́ tí ó ti kúrò ní ìlú títí di àsìkò yìí.”
7 A hele mai o Elisai i Damaseko: a he mai ko Benehadada ke alii o Suria: a ua haiia ia ia, i ka i ana'ku, Ua hiki mai ke kanaka o ke Akua ia nei.
Eliṣa lọ sí Damasku, Beni-Hadadi ọba Siria ń ṣe àìsàn. Nígbà tí wọ́n sọ fún ọba pé, “Ènìyàn Ọlọ́run ti wá láti gbogbo ọ̀nà òkè síbí,”
8 I aku la ke alii ia Hazaela, E lawe oe i ka makana ma kou lima, a hele aku e halawai me ke kanaka o ke Akua, a ninau aku ia Iehova ma o na la, i ka i ana'ku, E ola anei au i keia mai?
ọba sì wí fún Hasaeli pé, “Mú ọrẹ lọ́wọ́ rẹ, sì lọ pàdé ènìyàn Ọlọ́run. Kí o sì béèrè Olúwa láti ọ̀dọ̀ rẹ̀, béèrè lọ́wọ́ rẹ̀ pé ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn yìí?”
9 A hele aku la o Hazaela e halawai me ia, a lawe aku i ka makana ma kona lima, i kela mea, keia mea maikai o Damaseko, i kaumaha na kamelo he kanaha, a hele aku a ku imua ona, i aku la, O kau keiki, o Benehadada, ke alii o Suria, ua hoouna mai ia'u i ou la, i ka i ana mai, E ola anei au i keia mai?
Hasaeli lọ láti pàdé Eliṣa, ó mú lọ pẹ̀lú rẹ̀ ẹ̀bùn gẹ́gẹ́ bí ogójì ẹrù ìbákasẹ tí gbogbo ìní tí ó dára jù fún wíwò ti Damasku, ó sì wọlé lọ ó sì dúró níwájú rẹ̀, ó sì wí pé, “Ọmọ rẹ Beni-Hadadi ọba Siria rán mi láti béèrè pé, ‘Ṣé èmi yóò sàn nínú àìsàn mi yìí?’”
10 I mai la o Elisai ia ia, O hele, e i aku ia ia, He mea hiki ke ola io no oe; aka, ua hoike mai o Iehova ia'u, e make io no ia.
Eliṣa da á lóhùn pé, “Lọ kí o lọ sọ fún un pé, ‘Ìwo ìbá sàn nítòótọ́’; ṣùgbọ́n Olúwa ti fihàn mí pé nítòótọ́ òun yóò kùú.”
11 Haka pono aku la kona maka, a hilahila iho la: a uwe iho la ke kanaka o ke Akua.
Ó sì ranjú mọ́ ọn pẹ̀lú àtẹjúmọ́ gidigidi títí tí ojú fi ti Hasaeli. Nígbà náà ènìyàn Ọlọ́run bẹ̀rẹ̀ sí ní sọkún.
12 Ninau aku la o Hazaela, No ke aha la e uwe nei kuu haku? I mai la ia, No ka mea, ua ike au i ka hewa au e hana mai ai auanei i na mamo a Iseraela: o ko lakou mau wahi paa, e puhi a u anei oe i ke ahi, a o ko lakou poe kanaka i waeia, e luku auanei oe i ka pahikaua, a e ulupa oe i ka lakou poe keiki, a e kaka aku i ka lakou poe wahine hapai.
“Kí ni ó dé tí olúwa mi fi ń sọkún?” Hasaeli béèrè. “Nítorí pé èmi mọ ibi tí ìwọ yóò ṣe sí Israẹli,” ó sì dáhùn pé, “Ìwọ yóò fi iná si odi agbára wọn, ìwọ yóò, pa àwọn ọ̀dọ́ ọmọkùnrin wọn pẹ̀lú idà, ìwọ yóò kọlù àwọn ọmọ wẹ́wẹ́ wọn, ìwọ ó sì fọ́ wọn túútúú, ìwọ o sì la inú àwọn aboyún wọn.”
13 I aku la o Hazaela, Pehea la ia, he ilio anei kau kauwa, i hana aku ai ia i keia mea nui? I mai la o Elisai, Ua hoike mai o Iehova ia'u, e lilo auanei oe i alii maluna o Suria.
Hasaeli sì wí pé. “Báwo ni ìránṣẹ́ rẹ, ajá lásán làsàn yóò ṣe ṣe irú nǹkan ńlá bẹ́ẹ̀?” “Olúwa ti fihàn mí pé ìwọ ni yóò jẹ ọba Siria,” Eliṣa dá a lóhùn.
14 A hele aku la ia mai o Elisai aku a hoi aku ia i kona haku; a ninau mai la kela ia ia, Heaha ka Elisai i olelo mai ai ia oe? I aku la ia ia, Ua i mai kela ia'u, e ola io no oe.
Nígbà náà Hasaeli fi Eliṣa sílẹ̀ ó sì padà sí ọ̀dọ̀ ọ̀gá rẹ̀. Nígbà tí Beni-Hadadi béèrè, “Kí ni ohun tí Eliṣa sọ fún ọ?” Hasaeli dá a lóhùn, “Ó sọ fún mi wí pé ìwọ yóò sàn nítòótọ́.”
15 A ia la mai, lawe aku ia i ka lole manoanoa, a hou iho la iloko o ka wai, a kau maluna o kona waha, a make iho la ia: a noho alii iho la o Hazaela ma kona hakahaka.
Ṣùgbọ́n ní ọjọ́ kejì ó mú aṣọ tí ó nípọn, ó sì kì í bọ inú omi ó sì tẹ̀ ẹ́ sí ojú ọba, bẹ́ẹ̀ ni ó sì kú. Nígbà náà Hasaeli sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
16 A i ka lima o ka makahiki o Iorama, ke keiki a Ahaba, ke alii oh Iseraela, a o Iehosapata, oia ke alii o ka Iuda, i alii ai o Iehorama ke keiki a Iehosapata ke alii o ka Iuda.
Ní ọdún karùn-ún ti Joramu ọmọ Ahabu ọba Israẹli, nígbà tí Jehoṣafati jẹ́ ọba Juda, Jehoramu ọmọ Jehoṣafati bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba Juda.
17 He kanakolu kumamalua na makahiki ona, i kona lilo ana i alii; a ewalu na makahiki ana i alii ai ma Ierusalema.
Ó jẹ́ ẹni ọdún méjìlélọ́gbọ̀n nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mẹ́jọ.
18 A hele no ia ma ka aoao o na'liio ka Iseraela e like me ka nana ana a ko ka hale o Ahaba, no ka mea, o i ke kaikamahine a Ahaba, oia kana wahine: a na hana hewa ia imua o Iehova.
Ó sì rìn ní ọ̀nà ọba Israẹli, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti lọ, nítorí ó fẹ́ ọmọbìnrin Ahabu ó sì ṣe ohun búburú níwájú Olúwa.
19 Aole i makemake o Iehova o luku mai i ka Iuda no Davida kana kau wa, e like me kana i olelo mai ai ia ia, e haawi mau loa nona i malamalama na kana poe mamo.
Bí ó tilẹ̀ jẹ́ pé, nítorí ti ìránṣẹ́ rẹ̀ Dafidi. Olúwa kò fẹ́ pa Juda run, ó ti ṣèlérí láti ṣètọ́jú ìmọ́lẹ̀ fún Dafidi àti àwọn ilé rẹ̀ títí láéláé.
20 I kona manawa, kipi ao la o ka Edoma mai lalo ae o ka lima o ka Iuda, e hoonoho lakou i alii maluna o lakou iho.
Ní àkókò Jehoramu, Edomu ṣọ̀tẹ̀ sí Juda, wọ́n sì gbé ọba tiwọn kalẹ̀.
21 A hele aku la o Iehorama i Zaira, a me na halekaa a pau me ia; a ku ae la ia i ka po, a luku aku la i ka Edoma e puni ana ia ia, a me na luna o na halekaa: a holo aku la na kanaka i ko lakou halelewa.
Bẹ́ẹ̀ ni Jehoramu lọ sí Sairi pẹ̀lú gbogbo kẹ̀kẹ́ rẹ̀. Àwọn ará Edomu sì yí i ká àti kẹ̀kẹ́ àwọn olórí wọn, ṣùgbọ́n ó dìde dúró ní òru; àwọn ogun rẹ̀ síbẹ̀síbẹ̀, sá padà lọ ilé.
22 Aka, kipi ae la ka Edoma mai lalo ae o ka lima o ka Iuda, a hiki i keia manawa. I kela manawa kipi ae la ko Libena.
Títí ó fi di òní, Edomu wà nínú ọ̀tẹ̀ lórí Juda, Libina ṣọ̀tẹ̀ ní àkókò kan náà.
23 A o na hana i koe a Iehorama, a o na mea a pau ana i hana'i, aole anei i kakauia lakou iloko o ka buke oihanaalii a na'lii o ka Iuda?
Gẹ́gẹ́ bí fún iṣẹ́ mìíràn ti ìjọba Jehoramu, àti gbogbo ohun tí ó ṣe, ṣé a kò ha kọ wọ́n sínú ìwé ọ̀rọ̀ ọjọ́ àwọn ọba Juda?
24 A hiamoe iho la o Iehorama me kona poe kupuna, a kanuia iho la me kona poe kupuna ma ke kulanakauhale o Davida: a noho alii iho la o Azaria kana keiki ma kona bakahaka.
Jehoramu sì sùn pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀ a sì sin ín pẹ̀lú wọn ní ìlú Dafidi, Ahasiah ọmọ rẹ̀ sì jẹ ọba ní ipò rẹ̀.
25 I ka umikumamalua o ka makahiki o Iorama, ke keiki a Ahaba, ke alii o ka Iseraela, i noho alii ai o Azaria, ke keiki a Iehorama, ke alii o ka Iuda.
Ní ọdún méjìlá Joramu ọmọkùnrin Ahabu ọba Israẹli, Ahasiah ọmọkùnrin Jehoramu ọba Juda bẹ̀rẹ̀ ìjọba rẹ̀.
26 He iwakalua kumamalua o ko Ahazia makahiki i kona lilo ana i alii, a hookahi makahiki ana i noho alii ai ma Ierusalema. A o Atalia ka inoa o kona makuwahine, ka moopuna a Omeri, ke alii o ka Iseraela.
Ahasiah jẹ́ ẹni ọdún méjìlélógún nígbà tí ó di ọba. Ó sì jẹ ọba ní ọdún kan ní Jerusalẹmu. Orúkọ ìyá rẹ̀ a sì máa jẹ́ Ataliah, ọmọbìnrin Omri ọba Israẹli.
27 A hele no ia ma ka aoao o ko ka hale o Ahaba, a hana hewa no ia imua o Iehova, e like me ko ka hale o Ahaba: no ka mea, he hunonakane no ia no ko ka hale o Ahaba.
Nígbà tí ó rin ọ̀nà ilé Ahabu ó sì ṣe búburú níwájú Olúwa, gẹ́gẹ́ bí ilé Ahabu ti ṣe, nítorí ó tan nípa ìgbéyàwó sí ìdílé Ahabu.
28 A hele pu aku la ia me Iorama ke keiki a Ahaba e kana aku ia Hazaela ke alii o Suria ma Ramota-Gileada: a hahau mai ko Suria ia Iorama.
Ahasiah sì lọ pẹ̀lú Joramu ọmọ Ahabu lọ sí ogun lórí Hasaeli ọba Aramu ní Ramoti Gileadi. Àwọn ará Siria ṣẹ́ Joramu lẹ́sẹ̀.
29 A hoi aku la o Iorama ke alii i Iezereela e hoolaia i ka eha a ko Suria i hana eha ai ia ia ma Ramota, i ka manawa ana i kana aku ai ia Hazaela ke alii o Suria. A hele mai o Ahazia, ke keiki a Iehorama, ke alii o ka Iuda, e ike ia Iorama, no ka mea, ua eha ia.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba Joramu padà sí Jesreeli láti wo ọgbẹ́ rẹ̀ sàn tí ará Siria ti jẹ ní yà lórí rẹ̀ ní Ramoti ní ojú ogun rẹ̀ pẹ̀lú Hasaeli ọba Aramu. Nígbà náà Ahasiah ọmọ Jehoramu ọba Juda sọ̀kalẹ̀ lọ sí Jesreeli láti lọ wo Joramu ọmọ Ahabu nítorí tí ó fi ara pa.

< II Na Lii 8 >