< II Na Lii 22 >

1 E WALU na makahiki o Iosia, i kona lilo ana i alii, a he kanakolukumamakahi na makahiki ana i noho alii ai ma Ierusalema. A o Iedida ka inoa o kona makuwahine, he kaikamahine a Adaia no Bosekata.
Josiah jẹ́ ọmọ ọdún mẹ́jọ nígbà tí ó di ọba, ó sì jẹ ọba ní Jerusalẹmu fún ọdún mọ́kànlélọ́gbọ̀n. Orúkọ ìyá rẹ̀ a máa jẹ́ Jedida ọmọbìnrin Adaiah; ó wá láti Boskati.
2 A hana pono aku la ia imua o Iehova, a hele no ia ma na aoao o Davida kona kupuna, aole ia i huli ae ma ka akau, aole ma ka hema.
Ó sì ṣe èyí tí ó dára lójú Olúwa, ó sì rìn ní ọ̀nà Dafidi baba a rẹ̀, kò sì yípadà sí apá ọ̀tún tàbí sí apá òsì.
3 A i ka makahiki umikumamawalu o Iosia ke alii, hoouna aku la ke alii ia Sapana ke keiki a Azalia, ke keiki a Mesulama, ke kakauolelo, i ka hale o Iehova, i aku la,
Ní ọdún kejìdínlógún tí ó fi jẹ ọba. Ọba Josiah rán akọ̀wé, Ṣafani ọmọ Asalia, ọmọ Meṣullamu, sí ilé Olúwa. Ó wí pé,
4 E pii aku oe ia Hilekia ke kahuna nui, a nana e helu ke kala i laweia mai iloko o ka hale o Iehova, ka mea a ka poe kiai i ka paepae puka i hoiliili ae na na kanaka mai.
“Gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ Hilkiah olórí àlùfáà, kí o sì jẹ́ kí ó ṣírò iye owó tí a mú wá sí ilé Olúwa, tí àwọn olùṣọ́nà ti gbà lọ́wọ́ àwọn ènìyàn.
5 A e haawi aku lakou ia mea i ka lima o ka poe hana i ka hana, i ka poe luna hoi o ka hale o Iehova, a e haawi aku hoi lakou i ka poe hana i ka hana maloko o ka hale o Iehova, no ka hana hou i kahi naha o ka hale.
Ẹ sì jẹ́ kí wọn ó fi lé àwọn ọkùnrin tí a ti yàn láti bojútó iṣẹ́ náà lórí ilé Olúwa. Kí ẹ sì jẹ́ kí àwọn ọkùnrin san án fún àwọn òṣìṣẹ́ tí ó ń tún ilé Olúwa ṣe.
6 A i na kamana, a i ka poe kukulu, a i ka poe hahao pohaku, a me ke kuai laau a me na pohaku i kalaiia no ka hana hou i ka hale.
Àwọn gbẹ́nàgbẹ́nà, àwọn ọ̀mọ̀lé àti àwọn akọ́lé. Bákan náà ni wọ́n ra igi àti òkúta ọlọ́ṣọ̀ọ́ láti fi tún tẹmpili ṣe.
7 Aka, aole i helu pu ia me lakou ke kala i haawiia i ko lakou lima, no ka mea, ma ka pono ka lakou hana ana.
Ṣùgbọ́n wọn kò ní láti ṣe ìṣirò fún owó náà tí a fi fún wọn, nítorí wọ́n ṣe òtítọ́.”
8 I aku la o Hilekia ke kahuna nui ia Sapana ke kakauolelo, Ua loaa ia'u ka buke o ke kanawai ma ka hale o Iehova. A haawi aku la o Hilekia i ka buke ia Sapana, a heluhelu no kela ia mea.
Hilkiah olórí àlùfáà sọ fún Ṣafani akọ̀wé pé, “Èmi rí ìwé òfin nílé Olúwa.” Ó fi fún Ṣafani, ẹni tí ó kà á.
9 A hele aku la o Sapana ke kakauolelo i ke alii, a hai aku i ka olelo i ke alii, i aku la, Ua ninini kau mau kauwa i ke kala i loaa iloko o ka hale, a ua haawi aku ia mea i ka poe hana i ka hana, i na luna o ka hale o Iehova.
Nígbà náà, Ṣafani akọ̀wé lọ sí ọ̀dọ̀ ọba. Ó sì sọ fún un pé, “Àwọn ìjòyè rẹ ti san owó náà tí ó wà nínú ilé Olúwa. Èmi sì ti fi lé ọwọ́ àwọn tí ó ń ṣe iṣẹ́ náà àti àwọn alábojútó nílé Olúwa.”
10 A hai aku la o Sapana, ke kakauolelo i ke alii, i aku la, O Hilekia ke kahuna, ua haawi mai ia'u i buke. A heluhelu iho la o Sapana ia mea imua o ke alii.
Nígbà náà Ṣafani akọ̀wé sọ fún ọba pé, “Hilkiah àlùfáà ti fún un ní ìwé kan.” Ṣafani kà lára rẹ̀ níwájú ọba.
11 A lohe ke alii i ka olelo a ka buke o ke kanawai, haehae iho la ia i kona aahu.
Nígbà tí ọba gbọ́ ọ̀rọ̀ tí ó wà nínú ìwé òfin, ó sì fa aṣọ rẹ̀ ya.
12 A kauoha aku la ke alii ia Hilekia ke kahuna, a ia Ahikama, ke keiki a Sapana, a ia Akebora ke keiki a Mikaia, a ia Sapana ke kakauolelo, a ia Asakia, ke kauwa a ke alii, i aku la,
Ó pa àṣẹ yìí fún Ahikamu àlùfáà, Hilkiah ọmọ Ṣafani, Akbori ọmọ Mikaiah, àti Ṣafani akọ̀wé àti Asaiah ìránṣẹ́ ọba.
13 E hele oukou, a e ninau aku ia Iehova no'u, a no na kanaka, a no ka Iuda a pau, i na olelo o keia buke i loaa; no ka mea, ua nui ka inaina o Iehova i hoaia no kakou, i ka hoolohe ole o ko kakou poe makua i na olelo o keia buke, e hana like me na mea a pau i kakauia no kakou.
“Lọ, ẹ béèrè lọ́wọ́ Olúwa fún mi àti fún àwọn ènìyàn àti fún gbogbo Juda nípa ohun tí a kọ sínú ìwé yìí tí a ti rí. Títóbi ni ìbínú Olúwa tí ó ń jó sí wa nítorí àwọn baba wa kò tẹ̀lé ọ̀rọ̀ inú ìwé yìí; wọn kò ṣe ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ níbẹ̀ nípa wa.”
14 A hele aku la o Hilekia ke kahuna, a me Ahikama, a me Akebora, a me Sapana, a me Asakia, io Huleda la ke kaula wahine, ka wahine a Saluma, ke keiki a Tikeva, ke keiki a Harehasa, nana i malama i na aahu; (a e noho ana ua wahine la ma Ierusalema, ma kekahi hapa, ) a kamailio pu lakou me ia.
Hilkiah àlùfáà, Ahikamu àti Akbori Ṣafani pẹ̀lú Asaiah, lọ sí ọ̀dọ̀ wòlíì obìnrin Hulda láti lọ bá a sọ̀rọ̀, ẹni tí ó jẹ́ aya Ṣallumu ọmọ Tikfa ọmọ Harhasi alábojútó ibi ìpa aṣọ mọ́ sí. Ó ń gbé ní Jerusalẹmu ní ìdàkejì.
15 I mai la kela ia lakou, Ke olelo mai nei o Iehova ke Akua o ka Iseraela peneia, E olelo aku oukou i ke kanaka, nana oukou i hoouna mai io'u nei,
Ó wí fún wọn pé, “Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí, Sọ fún ọkùnrin tí ó rán an yín sí mi,
16 Ke olelo mai nei o Iehova peneia, Aia hoi, e lawe mai ana au i ka ino maluna o keia wahi, a maluna o kona poe kanaka, i na mea a pau o ka buke a ke alii o ka Iuda i heluhelu ai:
‘Èyí ni ohun tí Olúwa wí: Èmi yóò mú ibi wá sí ibí àti àwọn ènìyàn rẹ ní ìbámu pẹ̀lú gbogbo ohun tí a kọ sínú ìwé tí ọba Juda ti kà.
17 No ka mea, ua haalele lakou ia'u, a na kuni i ka mea ala i na akua e, i hoonaukiuki ai lakou ia'u, ma na hana a pau a ko lakou lima; nolaila, e hoaia ko'u inaina i keia wahi, aole ia e pio.
Nítorí tí wọ́n ti kọ̀ mí sílẹ̀, wọ́n sì tún sun tùràrí fún ọlọ́run mìíràn. Wọ́n sì mú mi bínú nípa gbogbo àwọn òrìṣà tí wọ́n ti fi ọwọ́ wọn dá. Ìbínú mi yóò ru sí ibí yìí, kì yóò sì rọlẹ̀.’
18 Aka, i ke alii o ka Iuda, nana oukou i hoouna mai nei e ninau ia Iehova, peneia oukou e olelo aku ai ia ia, Ke olelo mai nei o Iehova ke Akua o ka Iseraela peneia, no na olelo au i lohe ai;
Sọ fún ọba Juda tí ó rán yín láti béèrè lọ́wọ́ Olúwa, ‘Èyí ni ohun tí Olúwa Ọlọ́run Israẹli wí nípa ọ̀rọ̀ wọ̀n-ọn-nì tí ìwọ ti gbọ́.
19 No ka mea, ua akahai kou naau, a ua hoohaahaa oe ia oe iho imua o Iehova i ka wa i lohe ai oe i ka mea a'u i olelo ai no keia wahi, a me kona poe kanaka, i lilo ai lakou i mea kahahaia, a i mea hoinoia, a ua haehae oe i kou aahu, a ua auwe oe imua o'u; owau hoi ka i hoolohe, wahi a Iehova.
Nítorí tí ọkàn rẹ rọ̀, tí ìwọ sì ti rẹ ara rẹ sílẹ̀ níwájú Olúwa, nígbà tí ìwọ gbọ́ èyí tí mo sọ sí ibí yìí àti sí àwọn ènìyàn rẹ pé wọn yóò di ahoro àti ẹni ègún tí ìwọ sì fa aṣọ ọ̀ rẹ ya pẹ̀lú níwájú mi. Èmi ti gbọ́ tìrẹ, ni Olúwa wí.
20 Nolaila hoi e hui pu aku au ia oe me kou poe kupuna, a ma kou halelua oe e huiia'i me ka malu; aole hoi e ike kou mau maka i ka ino a pau a'u e lawe mai ai maluna o keia wahi. A hai aku la lakou i ke alii i ka olelo.
Nítorí náà èmi yóò kó ọ jọ sí ọ̀dọ̀ àwọn baba à rẹ, a ó sì sin ọ́ ní àlàáfíà. Ojú rẹ kì yóò rí gbogbo àwọn ibi tí èmi yóò mú wá bá ibí yìí.’” Bẹ́ẹ̀ wọ́n mú èsì rẹ̀ padà tọ ọba wá.

< II Na Lii 22 >