< II Na Lii 13 >
1 I KA makahiki iwakalua kumamakolu o Ioasa ke keiki a Ahazia ke alii o ka Iuda, i lilo ai o Iehoahaza, ke keiki a Iehu, i alii maluna o ka Iseraela ma Samaria, he umikumamahiku na makahiki o kona alii ana.
Ní ọdún kẹtàlélógún ti Joaṣi ọmọ ọba Ahasiah ti Juda, Jehoahasi ọmọ Jehu di ọba Israẹli ní Samaria. Ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́tàdínlógún.
2 A hana ino aku la ia imua o Iehova, a hele aku la ia mamuli o ka hewa o Ieroboama ke keiki a Nebata, nana i hoolilo ka Iseraela i ka hewa; aole ia i haalele ia mea.
Ó ṣe búburú níwájú Olúwa nípa títẹ̀lé ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati, èyí tí ó ti fa Israẹli láti dá, kò sì yípadà kúrò nínú wọn.
3 A hoaia ka inaina o Iehova i ka Iseraela, a haawi aku la ia ia lakou iloko o ka lima o Hazaela, ke alii o Suria, a iloko o ka lima o Benehadada, he keiki a Hazaela i na la a pau.
Bẹ́ẹ̀ ni ìbínú Olúwa ru sí àwọn ọmọ Israẹli, àti fún ìgbà pípẹ́, ó fi wọ́n pamọ́ sí abẹ́ agbára ọba Hasaeli ọba Siria àti Beni-Hadadi ọmọ rẹ̀.
4 A nonoi aku la o Iehoahaza ia Iehova, a hoolohe mai o Iehova ia ia: no kona ike ana i ke kaumaha o ka Iseraela, no ka mea, ua hookaumaha ke alii o Suria ia lakou.
Nígbà náà Jehoahasi kígbe ó wá ojúrere Olúwa, Olúwa sì tẹ́tí sí i. Nítorí ó rí bí ọba Siria ti ń ni Israẹli lára gidigidi.
5 (A haawi mai la o Iehova i ka Iseraela i mea e pakele ai, a puka aku lakou mai lalo mai o ka lima o ko Suria: a noho iho la na mamo a Iseraela ma ko lakou halelewa, e like me ka manawa mamua.
Olúwa pèsè olùgbàlà fún Israẹli, wọ́n sì sá kúrò lọ́wọ́ agbára Siria. Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ọmọ Israẹli gbé nínú ilé ara wọn gẹ́gẹ́ bí wọ́n ti wà tẹ́lẹ̀.
6 Aka, aole lakou i huli mai mai ka hewa mai o ko ka hale o Ieroboama, nana i hoolilo ka Iseraela i ka hewa, aka, hahai no lakou malaila: a e waiho ana hoi o Asetarota ma Samaria.)
Ṣùgbọ́n wọn kò yípadà kúrò nínú ẹ̀ṣẹ̀ ilé Jeroboamu, èyí tí ó ti fa Israẹli láti dá, wọ́n tẹ̀síwájú nínú rẹ̀, ère òrìṣà Aṣerah sì wà síbẹ̀ ní Samaria pẹ̀lú.
7 A i waiho iho la ia i na kanaka no Iehoahaza, he kanalima hoohololio, he umi na halekaa, a he umi tausani koa hele wawae wale no; no ka mea, ua luku aku ke alii o Suria ia lakou, a ua hoolike aku ia lakou me ka lepo no ka hehi ana.
Kò sí ohùn kan tí wọ́n fi sílẹ̀ ní ti ọmọ-ogun Jehoahasi àyàfi àádọ́ta ọkùnrin ẹlẹ́ṣin, kẹ̀kẹ́ mẹ́wàá, àti ẹgbẹ̀rún mẹ́wàá ọmọ-ogun ẹlẹ́ṣẹ̀, nítorí ọba Siria ti pa ìyókù run, ó sì ṣe wọ́n bí eruku nígbà pípa ọkà.
8 A o na hana i koe a Iehoahaza, a o na mea a pau ana i hana'i, a me kona ikaika, aole anei i kakauia lakou iloko o ka buke oihanaalii a na'lii o ka Iseraela?
Fún ti ìyókù ìṣe Jehoahasi fún ìgbà, tí ó fi jẹ ọba, gbogbo ohun tí ó ṣe àti àṣeyọrí rẹ̀ ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
9 A hiamoe iho la o Iehoahaza me kona poe kupuna; a kanu iho la lakou ia ia ma Samaria: a o Ioasa kana keiki, nohoalii iho la ia ma kona wahi.
Jehoahasi pẹ̀lú àwọn baba rẹ̀. A sì sin ín sí Samaria. Jehoaṣi ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
10 I ka makahiki kanakolukumamahiku o Ioasa ke alii o ka Iuda, i lilo ai o Iehoasa, ke keiki a Iehoahaza, i alii maluna o ka Iseraela ma Samaria, a he umikumamaono na makahiki o kona alii ana.
Ní ọdún kẹtàdínlógójì tí Joaṣi ọba Juda, Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi di ọba Israẹli ní Samaria ó sì jẹ ọba fún ọdún mẹ́rìndínlógún.
11 A hana ino aku la ia imua o Iehova, aole ia i haalele i na hewa a pau o Ieroboama ke keiki a Nebata, nana i hoolilo ka Iseraela i ka hewa; aka, hele no ia malaila.
Ó ṣe búburú ní ojú Olúwa, kò sì yípadà kúrò nínú ọ̀kankan nínú ẹ̀ṣẹ̀ Jeroboamu ọmọ Nebati èyí tí ó ti ti Israẹli láti fà. Ó sì tẹ̀síwájú nínú wọn.
12 A o na hana i koe o Ioasa, a o na mea a pau ana i hana'i, a me kona ikaika ana i kana aku ai ia Amazia ke alii o ka Iuda, aole anei i kakauia lakou iloko o ka buke oihanaalii a na'lii o ka Iseraela?
Fún ti ìyókù iṣẹ́ Jehoaṣi fún ìgbà tí ó fi jẹ ọba, gbogbo ohun tí ó ṣe, pẹ̀lú àṣeyọrí rẹ̀ pẹ̀lú ogun rẹ̀ sí Amasiah ọba Juda, ṣé a kò kọ wọ́n sínú ìwé ìtàn ayé àwọn ọba Israẹli?
13 A hiamoe iho la o Ioasa me kona poe kupuna; a noho iho la o Ieroboama maluna o kona nohoalii: a kanuia iho la o Ioasa ma Samaria me na'lii o ka Iseraela.
Jehoaṣi sinmi pẹ̀lú àwọn baba a rẹ̀. Jeroboamu sì rọ́pò rẹ̀ lórí ìtẹ́. A sin Jehoaṣi sí Samaria pẹ̀lú àwọn ọba Israẹli.
14 A mai iho la o Elisai, o kona mai ia i make ai. A iho mai o Ioasa, ke alii o ka Iseraela io na la, a auwe iho la maluna o kona maka, i aku la, E kuu makua, e kuu makua, o ka halekaa o ka Iseraela a me na hoohololio ona.
Nísinsin yìí, Eliṣa ń jìyà lọ́wọ́ àìsàn, lọ́wọ́ èyí tí ó sì kú. Jehoaṣi ọba Israẹli lọ láti lọ wò ó, ó sì sọkún lórí rẹ̀. “Baba mi! Baba mi!” Ó sọkún. “Àwọn kẹ̀kẹ́ àti àwọn ọkùnrin ẹlẹ́ṣin Israẹli!”
15 I aka la o Elisai ia ia, E lawe i kikoo a me na pua. A lawe ae la ia nona i kikoo a me na pua.
Eliṣa wí pé, “Mú ọrun kan àti àwọn ọfà,” ó sì ṣe bẹ́ẹ̀.
16 I aku la ia i ke alii o ka Iseraela, E kau aku i kou lima maluna o ke kikoo. A kau iho la ia i kona lima; a kau aku la o Elisai i kona mau lima maluna o na lima o ke alii.
“Mú ọrun ní ọwọ́ rẹ.” Ó wí fún ọba Israẹli. Nígbà tí ó ti mú u, Eliṣa mú ọwọ́ rẹ̀ lé ọwọ́ ọba.
17 I aku la ia, E wehe ae i ka pukamakani ma ka hikina. A wehe ae la ia. Alaila i aku la o Elisai, E pana aku: a pana aku la ia. I aku la ia, O ka pua hoola no Iehova, a o ka pua hoola mai ko Suria mai: no ka mea, e pepehi auanei oe i ko Suria ma Apeka, a pau i ka lukuia.
“Ṣí fèrèsé apá ìlà-oòrùn,” ó wí, pẹ̀lú ó sì ṣí i: “Ta á!” Eliṣa wí, ó sì ta á. “Ọfà ìṣẹ́gun Olúwa; ọfà ìṣẹ́gun lórí Siria!” Eliṣa kéde. “Ìwọ yóò pa àwọn ará Siria run pátápátá ní Afeki.”
18 I aku la ia, E lawe i na pua. A lawe iho la no ia. I aku la ia i ke alii o ka Iseraela, E hahau i ka honus. A hahau iho la ia, ekolu hahau ana, a oki.
Nígbà náà ó wí pé, “Mú àwọn ọfà náà,” ọba sì mú wọn. Eliṣa wí fún un pé, “Lu ilẹ̀.” Ó lù ú lẹ́ẹ̀mẹ́ta, ó sì dáwọ́ dúró.
19 A huhu aku la ke kanaka o ke Akua ia ia, i aku la, O kau pono no, i elima, a i eono paha hahau ana, alaila ua hahau iho oe i ko Suria, a pau i ka lukuia: aka, ano, e hahau aku oe i ko Suria i ekolu hahau ana wale no.
Ènìyàn Ọlọ́run sì bínú sí i, ó sì wí pé, “Ìwọ kò bá ti lu ilẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀márùn ún tàbí ní ẹ̀ẹ̀mẹ́fà, nígbà náà, ìwọ kò bá ti ṣẹ́gun Siria àti pa á run pátápátá ṣùgbọ́n nísinsin yìí, ìwọ yóò ṣẹ́gun rẹ̀ ní ẹ̀ẹ̀mẹ́ta péré.”
20 A make iho la o Elisai, a kanu iho la lakou ia ia. A hele mai ka poe hao wale o ka Moaba i ka aina, i ka hiki ana mai o ka makahiki.
Eliṣa kú a sì sin ín. Ẹgbẹ́ àwọn ará Moabu máa ń wọ orílẹ̀-èdè ní gbogbo àmọ́dún.
21 A i ko lakou kanu ana i kekahi kanaka, aia hoi, ike aku la lakou i ka poe hao wale, hoolei aku la lakou i ke kanaka iloko o ka halelua o Elisai; a i ka iho ana o ke kanaka a pili i na iwi o Elisai, ola mai la ia, a ku maluna o kona wawae.
Bí àwọn ọmọ Israẹli kan ti ń sin òkú ọkùnrin kan, lójijì wọ́n rí ẹgbẹ́ àwọn oníjadì, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n ju òkú ọkùnrin náà sínú ibojì Eliṣa. Nígbà tí ara ọkùnrin náà kan egungun Eliṣa, ó padà wá sí ayé, ó sì dúró ní ẹsẹ̀ rẹ̀.
22 A o Hazaela ko alii o Suria, hookaumaha aku la ia i ka Iseraela i na la a pau o Iehoahaza.
Hasaeli ọba Siria ni Israẹli lára ní gbogbo àkókò tí Jehoahasi fi jẹ ọba.
23 A manao mai o Iehova ia lakou, a ahonui mai ia lakou, a nana mai ia lakou no kana berita ia Aberahama, ia Isaaka, a me Iakoha, aole ona makemake e luku aku ia lakou, aole hoi e hookuke aku ia lakou mai kona alo aku i keia manawa.
Ṣùgbọ́n Olúwa ṣàánú fún wọn ó sì ní ìyọ́nú, ó sì fiyèsí wọn nítorí májẹ̀mú rẹ̀ pẹ̀lú Abrahamu, Isaaki àti Jakọbu. Títí di ọjọ́ òní, kì í ṣe ìfẹ́ inú rẹ̀ láti pa wọ́n run tàbí lé wọn lọ níwájú rẹ̀.
24 A make aku la o Hazaela ke alii o Suria; a noho alii iho la o Benehadada, kana keiki, ma kona hakahaka.
Hasaeli ọba Siria kú, Beni-Hadadi ọmọ rẹ̀ sì rọ́pò rẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ọba.
25 A hoi aku la o Iehoaza ke keiki a Iehoahaza, a lawe aku la i na kulanakauhale mai ka lima aku o Benehadada, ke keiki a Hazaela, i ka mea ana i lawe ae mai ka lima aku o Iehoahaza kona makuakane ma ke kaua ana. Lanakila aku la o Ioasa maluna ona, ekolu no lanakila ana, a hoihoi mai ia i na kulanakauhale o ka Iseraela.
Nígbà náà, Jehoaṣi ọmọ Jehoahasi gbà padà kúrò lọ́wọ́ Beni-Hadadi ọmọ Hasaeli àwọn ìlú tí ó ti gbà nínú ogun látọ̀dọ̀ baba rẹ̀ Jehoahasi. Ní ẹ̀ẹ̀mẹta, Jehoaṣi ṣẹ́gun rẹ̀, bẹ́ẹ̀ ni ó gba ìlú àwọn ọmọ Israẹli padà.