< II Oihanaalii 10 >
1 HELE aku la o Rhoboama i Sekema, no ka mea, ua hiki mai ka Iseraela a pau i Sekema e hoonoho ia ia i alii.
Rehoboamu sì lọ sí Ṣekemu nítorí gbogbo àwọn ọmọ Israẹli ti lọ síbẹ̀ láti fi jẹ ọba.
2 Lohe ae la o Ieroboama ke keiki a Nebata, e noho ana ia ma Aigupita kahi ana i mahuka aku ai mai ke alo aku o Solomona ke alii, a hoi mai o Ieroboama mai Aigupita mai.
Nígbà tí Jeroboamu ọmọ Nebati gbọ́ ẹni ti ó wà ní Ejibiti, níbi tí ó ti sá kúrò lọ́dọ̀ ọba Solomoni ó sì padà láti Ejibiti.
3 A hoouna aku la lakou a kahea aku ia ia; a hele mai o Ieroboama a me ka Iseraela a pau, a olelo mai la lakou ia Rehoboama, i mai la,
Bẹ́ẹ̀ ni nígbà náà ó sì ránṣẹ́ sí Jeroboamu àti òun àti gbogbo àwọn Israẹli lọ sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu wọ́n sì wí fún pé,
4 Ua hookaumaha kou makuakane i ka makou auamo, ano hoi, e hoomama iki i ka hana hooluhi a kou makuakane, a me ka auamo kaumaha ana i kau mai ai maluna o makou, a e hookauwa aku makou nau.
“Baba rẹ gbé àjàgà tí ó wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ mú un fúyẹ́, iṣẹ́ líle àti àjàgà wúwo tí ó gbé ka orí wa, àwa yóò sì sìn ọ́.”
5 Olelo aku la oia ia lakou, A hala na la ekolu, e hoi hou mai oukou i o'u nei. A hele aku la na kanaka.
Rehoboamu sì dáhùn pé, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi lẹ́yìn ọjọ́ mẹ́ta.” Bẹ́ẹ̀ ni àwọn ènìyàn náà sì lọ.
6 A ahaolelo pu iho la o Rehoboama ke alii me ka poe elemakule, ka poe i ku imua o Solomona, kona makuakane i ka wa o kona ola ana, i aku la, Heaha ka oukou e manao ai i mea e hai aku i keia poe kanaka?
Nígbà náà ni ọba Rehoboamu fi ọ̀ràn lọ̀ àwọn àgbàgbà tí ó ti ń sin baba rẹ̀ Solomoni nígbà ayé rẹ̀, ó sì bi wọ́n léèrè pe, “Báwo ni ẹ̀yin yóò ṣe gbà mí ní ìmọ̀ràn láti dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí lóhùn?”
7 Olelo lakou ia ia, i mai la, Ina e noho oe i mea e pono ai keia poe kanaka, a e hooluolu aku, a olelo i na mea maikai ia lakou, alaila, e noho mau lakou i poe kauwa nau.
Wọ́n sì dáhùn, “Tí ìwọ yóò bá ṣe rere sí àwọn ènìyàn wọ̀nyí kí o sì ṣe ìre fún wọn, kí o sì fún wọn ní ìdáhùn rere, wọn yóò sì máa jẹ́ ìránṣẹ́ rẹ nígbà gbogbo.”
8 Aka, haalele ae la ia i ka oleloao a ka poe elemakule, ka mea a lakou i ao mai ai, a ahaolelo pu iho la me ka poe kanaka ui, ka poe i noho pu me ia a nui, a e ku ana hoi imua ona.
Ṣùgbọ́n Rehoboamu kọ ìmọ̀ràn náà tí àwọn àgbàgbà fi fún un, ó sì fi ọ̀rọ̀ lọ àwọn ọmọ ọkùnrin tí ó ti dàgbàsókè pẹ̀lú rẹ̀ tí wọ́n sì ń dúró níwájú rẹ̀.
9 I aku la oia ia lakou, Heaha ko oukou manao i mea e olelo aku ai kakou i keia poe kanaka, ka poe i olelo mai ia'u, me ka i ana mai, E hoomama iki i ka auamo a kou makua i kau mai ai maluna o makou.
Ó sì béèrè lọ́wọ́ wọn pé, “Kí ni ìmọ̀ràn yín? Báwo ni kí a ṣe dá àwọn ènìyàn wọ̀nyí tí wọ́n wí fún mi pé, ‘Mú kí àjàgà tí baba rẹ gbé lé wa kí ó fúyẹ́ díẹ̀.’”
10 Olelo mai la ka poe kanaka ui, ka poe i noho pu me ia a nui, i mai la, Penei kau e olelo aku ai i ka poe kanaka i olelo mai ia oe, i mai ana, Ua hookaumaha kou makuakane i ka makou auamo, ano hoi e hoomama iki i ka makou auamo; penei oe e olelo aku ai ia lakou, E oi aku ka manoanoa o ko'u manamana lima iki i ka puhaka o ko'u makuakane.
Àwọn ọ̀dọ́mọdé tí ó ti dàgbà pẹ̀lú rẹ dá a lóhùn pé, “Sọ fún àwọn ènìyàn tí ó wí fún ọ wí pé, ‘Baba rẹ gbé àjàgà wúwo lórí wa, ṣùgbọ́n mú àjàgà wa fúyẹ́,’ wí fún wọn pé, ‘Ìka ọwọ́ mi kékeré, ó nípọn ju ìbàdí baba mi lọ.
11 Ua kau mai la ko'u makuakane i auamo kaumaha maluna o oukou, aka hoi, e hoonui au i ka oukou auamo; ua hahau mai ko'u makuakane ia oukou i ka huipa, aka hoi, e hahau au ia oukou i na moohueloawa.
Baba mi gbé àjàgà wúwo ka orí yín; èmi yóò sì tún mú kí ó wúwo sì í. Baba mi fi pàṣán nà yín; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.’”
12 A hoi mai o Ieroboama a me ka poe kanaka a pau io Rehoboama la i ka po akolu, e like me ka ke alii i olelo aku ai, E hoi mai oukou io'u nei i ke kolu o ka la.
Ní ọjọ́ kẹta Jeroboamu àti gbogbo ènìyàn sì padà sí ọ̀dọ̀ Rehoboamu, gẹ́gẹ́ bí ọba ti sọ, “Ẹ padà wá sọ́dọ̀ mi ní ọjọ́ kẹta.”
13 Olelo kalaea aku la ke alii ia lakou; haalele ke alii o Rehoboama i ka oleloao a ka poe elemakule;
Nígbà náà ni ọba dá wọn lóhùn ní ọ̀nà líle. Rehoboamu ọba sì kọ̀ ìmọ̀ràn àwọn àgbàgbà sílẹ̀,
14 A olelo aku la ia lakou e like me ka oleloao a ka poe kanaka ui, i aku la, Ua hookaumaha ko'u makua i ka oukou auamo, aka, e hoonui au ia mea; ua hahau ko'u makuakane ia oukou i ka huipa, aka, owau hoi e hahau ia oukou i na moohueloawa.
Ó sì tẹ̀lé ìmọ̀ràn àwọn ọ̀dọ́mọdé, ó sì wí pé, “Baba mi mú kí àjàgà yín wúwo; èmi yóò sì mú kí ó wúwo jù bẹ́ẹ̀ lọ. Baba mi nà yín pẹ̀lú pàṣán; èmi yóò sì nà yín pẹ̀lú àkéekèe.”
15 Pela i hoolohe ole aku ai ke alii i na kanaka; no ka mea, no ke Akua mai keia i hooko ai o Iehova i ka olelo ana i olelo mai ai ma o Ahiia la no Silo ia Ieroboama i ke keiki a Nebata.
Bẹ́ẹ̀ ni ọba kò sì fetísí àwọn ènìyàn, nítorí ìṣẹ̀lẹ̀ wọ̀nyí wá láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run ni. Láti mú ọ̀rọ̀ Olúwa ṣẹ tí a ti sọ fún Jeroboamu ọmọ Nebati nípasẹ̀ Ahijah ará Ṣilo.
16 A ike ae la ka Iseraela a pau, aole i hoolohe ke alii ia lakou, olelo na kanaka i ke alii, i mai la, Heaha ko makou kuleana iloko o Davida? aohe o makou hooilina iloko o ke keiki a Iese; e hoi no kela kanaka keia kanaka a pau i kona halelewa, e ka Iseraela; ano, e nana oe i kou hale iho, e Davida. Pela i hoi ai ka Iseraela a pau i ko lakou mau halelewa.
Nígbà tí gbogbo Israẹli rí i wí pé ọba kọ̀ láti gbọ́ tiwọn, wọ́n sì dá ọba lóhùn wí pé, “Ìpín kí ní a ní nínú Dafidi, ìní wo ni a ní nínú ọmọ Jese? Ẹ lọ sí àgọ́ yín, ẹ̀yin Israẹli! Bojútó ilé rẹ, ìwọ Dafidi!” Bẹ́ẹ̀ ní gbogbo àwọn ọmọ Israẹli lọ sí ilé wọn.
17 A o ka poe mamo a Iseraela e noho ana iloko o na kulanakauhale o Iuda, nohoalii iho la o Rehoboama maluna o lakou.
Ṣùgbọ́n ní ti àwọn ọmọ Israẹli tí ń gbé ní ìlú Juda, Rehoboamu ń jẹ ọba lórí wọn.
18 Hoouna aku la ke alii o Rehoboama ia Hedorama i ka mea maluna o ka auhau ana, a hailuku na mamo a Iseraela ia ia, a make ia. Alaila, wikiwiki ae la ke alii o Rehoboama e pii maluna o kona hale kaa, a e holo i Ierusalema.
Ọba Rehoboamu rán Adoniramu jáde, ẹni tí ó wà ní ìkáwọ́ iṣẹ́ onírúurú, ṣùgbọ́n àwọn ọmọ Israẹli sọ ọ́ ní òkúta pa. Ọba Rehoboamu, gbìyànjú láti dé inú kẹ̀kẹ́ rẹ̀ ó sì sálọ sí Jerusalẹmu.
19 Pela i kipi ai o ka Iseraela i ka ohana a Davida a hiki i keia la.
Bẹ́ẹ̀ ni Israẹli sì wà ní ìṣọ̀tẹ̀ lórí ilé Dafidi títí fi di òní yìí.