< I Samuela 6 >

1 I NA malama ehiku i noho ai ka pahu o Iehova ma ka aina o ko Pilisetia.
Nígbà tí àpótí ẹ̀rí Olúwa sì ti wà ní agbègbè Filistini fún oṣù méje,
2 Kahea aku la ko Pilisetia i na kahuna, a me ka poe kilokilo, i aku la, Heaha ka makou e hana aku ai i ka pahu o Iehova? E hoike mai ia makou, me ke aha la makou e lawe aku ai ia mea ma kona wahi?
àwọn ará Filistini pe àwọn àlùfáà, àti àwọn alásọtẹ́lẹ̀, wọ́n sì sọ pé, “Kí ni kí a ṣe pẹ̀lú àpótí ẹ̀rí Olúwa? Sọ fún wa bí àwa yóò ti dá a padà sí ààyè rẹ̀.”
3 I mai la lakou, Ina e lawe aku oukou i ka pahu o ke Akua o ka Iseraela, mai lawe nele aku; aka, e hoihoi aku me ka mohaihala nona: alaila e hoolaia oukou, a e hoikeia hoi ia oukou ka mea i lawe ole ia aku ai kona lima mai o oukou aku.
Wọ́n dáhùn wí pé, “Tí ẹ bá dá àpótí ẹ̀rí Ọlọ́run ti àwọn ọmọ Israẹli padà, ẹ má ṣe dá a padà ní òfìfo, ṣùgbọ́n bí ó ti wù kí ó rí, ẹ fún un ní ẹbọ ẹ̀bi. Nígbà náà ni a ó mú un yín láradá, ẹ̀yin yóò sì mọ ìdí tí ọwọ́ rẹ̀ kò fi tí ì kúrò lára yín.”
4 Ninau aku la lakou, Heaha ka mohaihala a makou e hoihoi aku ai nona? I mai la lakou, Elima puupuu koko gula, elima iole gula, ma ka helu ana o na haku o ko Pilisetia: no ka mea, hookahi no mai maluna o lakou a pau, a maluna hoi o ko oukou mau haku.
Àwọn ará Filistini béèrè pé, “Irú ẹbọ ẹ̀bi wo ni kí a fi fún un?” Wọ́n dáhùn, “Wúrà oníkókó márùn-ún àti eku ẹ̀lírí wúrà márùn-ún, gẹ́gẹ́ bí iye àwọn aláṣẹ Filistini, nítorí àjàkálẹ̀-ààrùn kan náà ni ó kọlù yín àti olórí yín.
5 No ia mea, e hana oukou i na kii no ko oukou puupuu koko, a me na kii no ko oukou iole, nana i hana ino ka aina; a e hoonani aku oukou i ke Akua o ka Iseraela: malia paha e hoomama mai ia i kona lima mai luna ae o oukou, a me ko oukou mau akua, a me ko oukou aina.
Mọ àwòrán ààrùn oníkókó àti ti eku ẹ̀lírí yin tí ó ń ba orílẹ̀-èdè náà jẹ́ kí o sì bu ọlá fún Ọlọ́run Israẹli. Bóyá yóò gbé ọwọ́ rẹ̀ kúrò lára yín, lára ọlọ́run yín àti lára ilẹ̀ yín.
6 No ke aha la oukou, e hoopaakiki nei i ko oukou naau, e like me ko Aigupita, a me Parao i hoopaakiki ai i ko lakou naau? Ia ia i hana mana ai iwaena o lakou, aole anei ia i kuu aku ia lakou, a hele lakou?
Kí ni ó dé tí ẹ fi ń sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí àwọn ará Ejibiti àti Farao ti ṣe? Nígbà tí ó fi ọwọ́ líle mú wọn, ṣé wọn kò rán àwọn ọmọ Israẹli jáde kí wọn kí ó lè lọ ní ọ̀nà wọn?
7 No ia mea, e hana oukou i kaa hou, a lawe i na bipiwahine waiu elua, aole i kau ka auamo maluna o laua, a e nakii i na bipi ma ke kaa, a e lawe i ka laua mau keiki mai o laua aku la:
“Nísinsin yìí ẹ pèsè kẹ̀kẹ́ ẹrù tuntun sílẹ̀, pẹ̀lú màlúù méjì tí ó ti fi ọmú fún ọmọ, èyí tí a kò tí ì gba àjàgà sí ọrùn rí, kí ẹ sì so ó mọ́ kẹ̀kẹ́ náà, kí ẹ sì mú ọmọ wọn kúrò lọ́dọ̀ wọn wá sí ilé láti so.
8 A e lawe aku oukou i ka pahu o Iehova, a kau maluna o ke kaa, a e hahao i na mea gula a oukou e hoihoi aku i mohaihala nona maloko o kahi pahu ma ka aoao; a e hoouna aku oukou ia mea, i hele aku ia.
Kí ẹ sì gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa sí orí kẹ̀kẹ́ ẹrù àti kí ẹ̀yin sì kó àwọn ohun èlò wúrà tí ẹ̀yin fi fún un gẹ́gẹ́ bí ti ẹbọ ẹ̀bi sí inú àpótí ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀, kí ẹ̀yin kí ó sì rán an lọ,
9 A e nana oukou, ina paha e pii aku ia ma ke ala o kona mokuna, i Betesemesa, alaila, ua hana mai ia i keia ino nui no kakou: aka, i ole. alaila e ike kakou, aole kona lima i hahau mai ia kakou; ua hiki wale mai ia mea ia kakou.
ṣùgbọ́n kí ẹ sì máa ṣọ́ ọ. Tí ó bá ń lọ sí ilẹ̀ rẹ̀, ìlú rẹ̀, níhà Beti-Ṣemeṣi. Nígbà náà ni Olúwa mú àjálù ńlá yìí bá wa. Ṣùgbọ́n bí kò bá ṣe bẹ́ẹ̀ nígbà náà ni a mọ̀ pé kì í ṣe ọwọ́ rẹ̀ ni ó kọlù wá, ṣùgbọ́n ó wá bẹ́ẹ̀ ni.”
10 A hana aku la na kanaka pela; a lawe aku la i na bipiwahine waiu elua, a nakii ia laua ma ke kaa, a hoopaa lakou i ka laua mau keiki maloko o ka hale.
Nígbà náà ni wọ́n ṣe èyí. Wọ́n mú abo màlúù méjì, tí ń fi ọmú fún ọmọ, wọn mọ́ ara, wọ́n sì dè é ni ilé kẹ̀kẹ́ ẹrù, wọn sì so àwọn ọmọ wọn mọ́lẹ̀ ni ilé.
11 Kau aku la lakou i ka pahu o Iehova maluna o ke kaa, a i kekahi pahu me na iole gula, a me na kii o ko lakou puupuu koko.
Wọ́n gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé orí kẹ̀kẹ́ ní ẹ̀gbẹ́ rẹ̀ ni àpótí tí eku ẹ̀lírí wúrà àti àwòrán ààrùn oníkókó wà níbẹ̀.
12 A hele pololei aku la na bipi ma ke ala e hiki ai i Betesemesa, ma ke ala loa ka hele ana, a hele laua me ka uwo ana, aole laua i huli ae ma ka akau, aole hoi ma ka hema; a hele na haku o ko Pilisetia mahope o laua, a hiki i ka mokuna o Betesemesa.
Nígbà náà; àwọn màlúù lọ tààrà sí ìhà Beti-Ṣemeṣi, wọ́n ń lọ tààrà, wọ́n sì ń dún bí wọ́n ti ń lọ. Wọn kò yà sí ọ̀tún tàbí yà sí òsì. Àwọn aláṣẹ Filistini tẹ̀lé wọn títí dé ibodè Beti-Ṣemeṣi.
13 A e oki ana ko Betesemesa i ka lakou palaoa ma ke awawa: alawa ae la ko lakou maka iluna, a ike aku la i ka pahu, a olioli lakou i ka ike ana aku.
Nísinsin yìí, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi ń kórè jéró wọn ní pẹ̀tẹ́lẹ̀, nígbà tí wọ́n wo òkè tí wọ́n sì rí àpótí ẹ̀rí Olúwa, wọ́n yọ̀ níwájú rẹ̀.
14 A hele aku la ke kaa maloko o ka mahinaai o Iosua no Betesemesa, a ku malaila; a malaila ka pohaku nui; a wawahi lakou i ka laau o ke kaa, a kaumaha aku la lakou i na bipi i mohaikuni ia Iehova.
Kẹ̀kẹ́ ẹrù wá sí pápá Joṣua ti Beti-Ṣemeṣi, níbẹ̀ ni ó ti dúró ní ẹ̀bá àpáta ńlá kan. Àwọn ènìyàn gé igi ara kẹ̀kẹ́ ẹrù sí wẹ́wẹ́ wọ́n sì fi àwọn màlúù náà rú ẹbọ sísun sí Olúwa.
15 Lawe mai la na Levi i ka pahu o Iehova, a me kekahi pahu i waiho pu ai me ia me na mea gula maloko, a kau aku la ia mea maluna o ka pohaku nui; a kaumaha aku na kanaka o Betesemesa i na mohaikuni, a ia la, kaumaha aku la no hoi lakou i na mohai ia Iehova.
Àwọn ará Lefi gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa wá sí ìsàlẹ̀ pẹ̀lú àpótí tí ohun èlò wúrà wà níbẹ̀, wọ́n sì gbé wọn ka orí àpáta ńlá náà. Ní ọjọ́ náà, àwọn ará Beti-Ṣemeṣi rú ẹbọ sísun, wọ́n sì ṣe ìrúbọ sí Olúwa.
16 A ike aku la na haku elima o ko Pilisetia ia mea, hoi aku la lakou ma Ekerona ia la.
Àwọn aláṣẹ Filistini márààrún rí gbogbo èyí, wọ́n sì padà ní ọjọ́ náà sí Ekroni.
17 Eia na puupuu koko gula a ko Pilisetia i hoihoi aku ai i mohaihala ia Iehova: no Asedoda kekahi, no Gaza kekahi, no Asekelona kekahi, no Gata kekahi, no Ekerona kekahi;
Èyí ni kókó wúrà tí àwọn Filistini fún Olúwa gẹ́gẹ́ bí ẹbọ ẹ̀bi ọ̀kọ̀ọ̀kan fún Aṣdodu, ọ̀kan ti Gasa, ọ̀kan ti Aṣkeloni, ọ̀kan ti Gati, ọ̀kan ti Ekroni.
18 A me na iole gula e like me ka helu ana o na kulanakauhale no na haku elima o ko Pilisetia, na kulanakauhale pa pohaku, a me na kauhale papu a hiki i ua pohaku nui o Abela, kahi a lakou i kau ai i ka pahu o Iehova; a ilaila ua pohaku la ma ka mahinaai o Iosua no Betesemesa, a hiki i keia la.
Wúrà eku ẹ̀lírí jẹ́ iye ìlú tí àwọn aláṣẹ Filistini márààrún ti wá, ìlú olódi pẹ̀lú ìletò wọn. Àpáta ńlá náà, lórí èyí tí a gbé àpótí ẹ̀rí Olúwa lé jẹ́ ẹ̀rí títí di òní ní oko Joṣua ará Beti-Ṣemeṣi.
19 A luku mai ia i na kanaka o Betesemesa, no ka mea, ua nana lakou iloko o ka pahu o Iehova, luku mai ia i na kanaka, he kanalima no tausani, a he kanahiku kanaka ia. Auwe na kanaka, no ka Iehova pepehi ana mai i na kanaka me ka luku nui.
Ṣùgbọ́n Ọlọ́run kọlu díẹ̀ lára àwọn ọkùnrin Beti-Ṣemeṣi, ó pa àádọ́rin wọn, nítorí wọ́n ti wo inú àpótí ẹ̀rí Olúwa. Àwọn ènìyàn ṣọ̀fọ̀ nítorí àjálù ńlá tí Olúwa fi bá ọ̀pọ̀ wọn jà.
20 I ae la na kanaka o Betesemesa, Owai la ka mea hiki ke ku imua o Iehova keia Akua Hemolele? A ia wai la oia e hele aku mai o kakou aku?
Àwọn ọkùnrin ará Beti-Ṣemeṣi béèrè pé, “Ta ni ó le è dúró ní iwájú Olúwa Ọlọ́run mímọ́ yìí? Ọ̀dọ̀ ta ni àpótí ẹ̀rí Olúwa yóò gbà gòkè lọ láti ibí yìí?”
21 Hoouna aku la lakou i na elele i na kanaka o Kiriatiarima, i aku la, Ua hoihoi mai ko Pilisetia i ka pahu o Iehova; e iho mai oukou e lawe aku ia io oukou la.
Nígbà náà, wọ́n rán àwọn ìránṣẹ́ sí àwọn ènìyàn tí Kiriati-Jearimu wí pé, “Àwọn Filistini ti dá àpótí ẹ̀rí Olúwa padà. Ẹ sọ̀kalẹ̀ wá, kí ẹ gbé e gòkè lọ sí ọ̀dọ̀ yín.”

< I Samuela 6 >