< Zabura 136 >

1 Ku yi godiya ga Ubangiji, gama nagari ne shi.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa nítorí tí ó ṣeun;
2 Ku yi godiya ga Allahn alloli.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run àwọn ọlọ́run:
3 Ku yi godiya ga Ubangijin iyayengiji.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Olúwa àwọn olúwa,
4 Gare shi wanda shi kaɗai yake aikata abubuwan banmamaki,
Fún Òun nìkan tí ń ṣiṣẹ́ ìyanu ńlá;
5 Wanda ta wurin ganewarsa ya yi sammai,
Fún ẹni tí ó fi ọgbọ́n dá ọ̀run;
6 Wanda ya shimfiɗa duniya a kan ruwaye,
Fún ẹni tí ó tẹ́ ilẹ̀ lórí omi;
7 Wanda ya yi manyan haskoki,
Fún ẹni tí ó dá àwọn ìmọ́lẹ̀ ńlá;
8 Rana don tă yi mulkin yini,
Òòrùn láti jẹ ọba ọ̀sán;
9 Wata da taurari kuma don su yi mulkin dare;
Òṣùpá àti ìràwọ̀ láti jẹ ọba òru;
10 Gare shi wanda ya kashe’ya’yan fari Masar
Fún ẹni tí ó kọlu Ejibiti lára àwọn àkọ́bí wọn;
11 Ya kuma fitar da Isra’ila daga cikinsu
Ó sì mú Israẹli jáde kúrò láàrín wọn;
12 Da hannu mai ƙarfi da hannu mai iko;
Pẹ̀lú ọwọ́ agbára àti apá nínà;
13 Gare shi wanda ya raba Jan Teku biyu
Fún ẹni tí ó pín Òkun pupa ní ìyà;
14 Ya kawo Isra’ila ta tsakiyarsa,
Ó sì mú Israẹli kọjá láàrín rẹ̀
15 Amma ya share Fir’auna da mayaƙansa cikin Jan Teku;
Ṣùgbọ́n ó bi Farao àti ogun rẹ̀ ṣubú nínú Òkun pupa;
16 Gare shi wanda ya bi da mutanensa cikin hamada,
Fún ẹni tí ó sin àwọn ènìyàn rẹ̀ la aginjù já
17 Wanda ya buge manyan sarakuna,
Fún ẹni tí ó kọlu àwọn ọba ńlá;
18 Ya karkashe manyan sarakuna,
Ó sì pa àwọn ọba olókìkí
19 Sihon sarkin Amoriyawa
Sihoni, ọba àwọn ará Amori
20 Da kuma Og sarkin Bashan,
Àti Ogu, ọba Baṣani;
21 Ya kuma ba da ƙasarsu gādo,
Ó sì fi ilẹ̀ wọn fún ni ní ìní,
22 Gādo ga bawansa Isra’ila;
Ìní fún Israẹli, ìránṣẹ́ rẹ̀,
23 Shi wanda ya tuna da mu cikin ƙasƙancinmu
Ẹni tí ó rántí wa ní ìwà ìrẹ̀lẹ̀ wa;
24 Ya kuma’yantar da mu daga abokan gābanmu,
Ó sì dá wa ní ìdè lọ́wọ́ àwọn ọ̀tá wa;
25 Wanda kuma ke ba da abinci ga kowace halitta.
Ẹni tí ó fi oúnjẹ fún àwọn ẹ̀dá gbogbo
26 Ku yi godiya ga Allah na sama.
Ẹ fi ọpẹ́ fún Ọlọ́run ọ̀run;

< Zabura 136 >