< Zekaria 9 >
1 Ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyũkĩrĩire bũrũri wa Hadaraka, na ĩgakinyĩrĩra Dameski: nĩgũkorwo maitho ma andũ, na ma mĩhĩrĩga yothe ya Isiraeli macũthĩrĩirie Jehova,
Ọ̀rọ̀-ìmọ̀. Ọ̀rọ̀ Olúwa kọjú ìjà sí Hadiraki, Damasku ni yóò sì jẹ́ ibi ìsinmi rẹ̀; nítorí ojú Olúwa ń bẹ lára ènìyàn, àti lára gbogbo ẹ̀yà Israẹli.
2 na ĩgakinyĩrĩra Hamathu o nakuo, itũũra rĩrĩa rĩhakanĩte nakuo, o na ĩgakinyĩrĩra Turo na Sidoni, o na gũtuĩka andũ akuo maarĩ oogĩ mũno.
Àti Hamati pẹ̀lú yóò ṣe ààlà rẹ̀ Tire àti Sidoni bí o tilẹ̀ ṣe ọlọ́gbọ́n gidigidi.
3 Andũ a Turo nĩmeyakĩire kĩĩgitĩro kĩrũmu, na makeigĩra hĩba cia betha nyingĩ ta rũkũngũ, na thahabu nyingĩ ta mahuti ma njĩra-inĩ.
Tire sì mọ odi líle fún ara rẹ̀, ó sì kó fàdákà jọ bí eruku, àti wúrà dáradára bí ẹrẹ̀ ìgboro.
4 No rĩrĩ, Mwathani nĩakarĩtunya ũtonga warĩo, na aanange ũhoti warĩo wa iria-inĩ, narĩo itũũra rĩu nĩrĩgacinwo na mwaki.
Ṣùgbọ́n, Olúwa yóò kó gbogbo ohun ìní rẹ̀ lọ, yóò sì pa agbára rẹ̀ run ní ojú Òkun, a ó sì fi iná jó o run.
5 Ashikeloni nĩrĩkeyonera ũhoro ũcio na rĩĩtigĩre, Gaza nĩrĩkehũũrithania nĩ ruo rũnene, o na Ekironi o narĩo, nĩgũkorwo mwĩhoko warĩo nĩũkahooha. Gaza nĩrĩkoorwo nĩ mũthamaki warĩo, narĩo Ashikeloni nĩrĩgathaamwo.
Aṣkeloni yóò rí í, yóò sì bẹ̀rù; Gasa pẹ̀lú yóò rí í, yóò sì káàánú gidigidi, àti Ekroni: nítorí tí ìrètí rẹ̀ yóò ṣákì í. Gasa yóò pàdánù ọba rẹ̀, Aṣkeloni yóò sì di ahoro.
6 Andũ a bũrũri ũngĩ nĩmagatũũra Ashidodi, na niĩ nĩnganiina mwĩtĩĩo wa Afilisti.
Ọmọ àlè yóò sì gbé inú Aṣdodu, Èmi yóò sì gé ìgbéraga àwọn Filistini kúrò.
7 Nĩngaruta thakame tũnua-inĩ twao, na irio iria ngaananie ndĩcirute gatagatĩ ka magego mao. Andũ arĩa magaatigara magaatuĩka a Ngai witũ, na matuĩke atongoria a Juda, nao andũ a Ekironi makahaana ta andũ a Jebusi.
Èmi yóò sì mu ẹ̀jẹ̀ rẹ̀ kúrò ni ẹnu rẹ̀, àti àwọn ohun èèwọ̀ kúrò láàrín eyín rẹ̀: ṣùgbọ́n àwọn tó ṣẹ́kù yóò jẹ́ tí Ọlọ́run wa, wọn yóò sì jẹ baálẹ̀ ní Juda, àti Ekroni ni yóò rí bí Jebusi.
8 Na rĩrĩ, nĩngagitĩra nyũmba yakwa kuuma kũrĩ mbũtũ iria imarehagĩra mbaara. Gũtirĩ hĩndĩ ĩngĩ mũhinyanĩrĩria agaacooka gũtooria andũ akwa, nĩgũkorwo rĩu nĩndĩĩoneire ũrĩa maanahinyĩrĩrio.
Èmi yóò sì dó yí ilẹ̀ mi ká nítorí ogun àwọn tí wọ́n ń wá ohun tí wọn yóò bàjẹ́ kiri, kò sí aninilára tí yóò bori wọn mọ́: nítorí ni ìsinsin yìí ni mo fi ojú ṣọ́ wọn.
9 Kena mũno, wee Mwarĩ wa Zayuni! Anĩrĩra, wee Mwarĩ wa Jerusalemu! Atĩrĩrĩ, mũthamaki waku nĩarooka kũrĩ we, nĩ mũthingu na arĩ na ũhonokio, nĩ mũhooreri na akuuĩtwo nĩ ndigiri, agaikarĩra njaũ ya ndigiri.
Kún fún ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Sioni, hó ìhó ayọ̀, ìwọ ọmọbìnrin Jerusalẹmu. Wò ó, ọba rẹ ń bọ̀ wá sọ́dọ̀ rẹ: òdodo ni òun, ó sì ní ìgbàlà; ó ní ìrẹ̀lẹ̀, ó sì ń gun kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́, àní ọmọ kẹ́tẹ́kẹ́tẹ́.
10 Nĩngeheria ngaari cia ita kuuma Efiraimu, na njeherie mbarathi cia mbaara kuuma Jerusalemu, naguo ũta wa mbaara-rĩ, nĩũkoinangwo. Nake aanĩrĩre thayũ ndũrĩrĩ-inĩ. Wathani wake-rĩ, ũgaatambũrũka kuuma iria rĩmwe nginya rĩrĩa rĩngĩ, na kuuma Rũũĩ rwa Farati o nginya ituri cia thĩ.
Èmi ó sì gbé kẹ̀kẹ́ kúrò ni Efraimu, àti ẹṣin ogun kúrò ni Jerusalẹmu, a ó sì ṣẹ́ ọrun ogun. Òun yóò sì kéde àlàáfíà sí àwọn kèfèrí. Ìjọba rẹ̀ yóò sì gbilẹ̀ láti Òkun dé Òkun, àti láti odò títí de òpin ayé.
11 No ha ũhoro waku-rĩ, nĩ ũndũ wa thakame ya kĩrĩkanĩro kĩrĩa ndarĩkanĩire nawe, nĩngoohorithia andũ aku arĩa mohetwo, moime irima rĩu rĩtarĩ maaĩ.
Ní tìrẹ, nítorí ẹ̀jẹ̀ májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ, Èmi ó dá àwọn ìgbèkùn rẹ̀ sílẹ̀ kúrò nínú ọ̀gbun.
12 Cookai kĩĩhitho-inĩ kĩanyu kĩrĩa kĩrũmu, inyuĩ muohetwo mũrĩ na mwĩhoko; o na rĩu nguuga atĩrĩ, nĩngamũcookeria indo cianyu maita meerĩ.
Ẹ padà sínú odi agbára yín, ẹ̀yin òǹdè ti o ni ìrètí: àní lónìí yìí èmi sọ pé, èmi o san án fún ọ ni ìlọ́po méjì.
13 Ngaagonya Juda o taarĩ ũta wakwa, nake Efiraimu atuĩke ta mĩguĩ ya ũta ũcio, ndĩmaiyũrie kuo. Nĩngarahũra ariũ aku, wee Zayuni, mokĩrĩre ariũ aku wee Mũyunani, na ngũtue ta rũhiũ rwa njora rwa njamba ĩrĩ hinya.
Èmi ó fa Juda le bí mo ṣe fa ọrun mi le, mo sì fi Efraimu kún un, Èmi yóò gbé àwọn ọmọ rẹ ọkùnrin dìde, ìwọ Sioni, sí àwọn ọmọ rẹ̀ ọkùnrin, ìwọ Giriki, mo ṣe ọ́ bí idà alágbára.
14 Hĩndĩ ĩyo Jehova nĩakoonwo arĩ igũrũ rĩao; mũguĩ wake ũkaarathũka ta rũheni. Mwathani Jehova nĩakahuha karumbeta; agaathiĩ arĩ ihuhũkanio-inĩ cia mwena wa gũthini,
Olúwa yóò sì fi ara hàn ní orí wọn; ọfà rẹ̀ yóò sì jáde lọ bí mọ̀nàmọ́ná. Olúwa Olódùmarè yóò sì fọn ìpè, Òun yóò sì lọ nínú atẹ́gùn ìjì gúúsù.
15 nake Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩakamagitĩra. Nao makaamaniina biũ, na matooranie na kũmahũũra na mahiga ma kĩgũtha. Makaanyua na manegene ta marĩĩtwo nĩ ndibei; makaiyũrĩrĩrio ta mbakũri ĩrĩa ĩhũthagĩrwo kũminjaminjĩria koine cia kĩgongona.
Olúwa àwọn ọmọ-ogun yóò dáàbò bò wọ́n; wọn ó sì jẹ ni run, wọn ó sì tẹ òkúta kànnàkànnà mọ́lẹ̀; wọn ó sì mu ẹ̀jẹ̀ wọn bí wáìnì, wọn ó sì kún bí ọpọ́n, wọn ó sì rin ṣinṣin bí àwọn igun pẹpẹ.
16 Jehova Ngai wao nĩakamahonokia mũthenya ũcio, marĩ andũ a rũũru rwake. Nĩmagakengaga bũrũri-inĩ wake, ta mahiga ma goro marĩ thũmbĩ-inĩ ya mũthamaki.
Olúwa Ọlọ́run wọn yóò sì gbà wọ́n là ni ọjọ́ náà bí agbo ènìyàn rẹ̀: nítorí wọn ó dàbí àwọn òkúta adé, tí a gbé sókè bí àmì lórí ilẹ̀ rẹ̀.
17 Kaĩ nĩmagakorwo marĩ a kwendeka, na mathakarĩte-ĩ! Irio cia mĩgũnda nĩigatũma aanake magaacĩre, nayo ndibei ya mũhihano ĩtũme airĩtu o nao magaacĩre.
Nítorí oore rẹ̀ tí tóbi tó, ẹwà rẹ̀ sì tí pọ̀! Ọkà yóò mú ọ̀dọ́mọkùnrin dárayá, àti ọtí wáìnì tuntun yóò mú àwọn ọ̀dọ́mọbìnrin ṣe bẹ́ẹ̀ pẹ̀lú.