< Zekaria 7 >
1 Na rĩrĩ, mwaka-inĩ wa ĩna wa ũthamaki wa Dario, ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire Zekaria, mũthenya wa kana wa mweri wa kenda, na nĩguo mweri wa Kiselevu.
Ó sì ṣe ní ọdún kẹrin Dariusi ọba, ọ̀rọ̀ Olúwa tọ́ Sekariah wá ni ọjọ́ kẹrin oṣù Kisleu tí ń ṣe oṣù kẹsànán.
2 Andũ a Betheli nĩmatũmĩte Sharezeru na Regemu-Meleku hamwe na andũ ao magathaithe Jehova
Nígbà tí wọ́n ènìyàn Beteli rán Ṣareseri àti Regemmeleki, àti àwọn ènìyàn wọn sí ilé Ọlọ́run láti wá ojúrere Olúwa.
3 na kũũria athĩnjĩri-Ngai a nyũmba ya Jehova Mwene-Hinya-Wothe na anabii atĩrĩ, “Nĩnjagĩrĩirwo nĩ gũcakaya na kwĩhinga kũrĩa irio mweri wa gatano, ta ũrĩa njĩkĩte mĩaka mĩingĩ?”
Àti láti bá àwọn àlùfáà tí ó wà ní ilé Olúwa àwọn ọmọ-ogun, àti àwọn wòlíì sọ̀rọ̀ wí pé, “Ṣé kí èmi ó sọkún ní oṣù karùn-ún kí èmi ya ara mi sọ́tọ̀, bí mo ti ń ṣe láti ọdún mélòó wọ̀nyí wá bí?”
4 Ningĩ ndũmĩrĩri ya Jehova Mwene-Hinya-Wothe nĩyanginyĩrire akĩnjĩĩra atĩrĩ,
Nígbà náà ni ọ̀rọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun tọ̀ mí wá pé,
5 “Ũria andũ othe a bũrũri o na athĩnjĩri-Ngai atĩrĩ, ‘Rĩrĩa mwehingaga kũrĩa irio mũgĩcakayaga mweri-inĩ wa gatano na wa mũgwanja ihinda rĩa mĩaka mĩrongo mũgwanja-rĩ, ti-itherũ mwehingaga kũrĩa irio nĩ ũndũ wakwa?
“Sọ fún gbogbo àwọn ènìyàn ilẹ̀ náà, àti fún àwọn àlùfáà pé, ‘Nígbà tí ẹ̀yin gbààwẹ̀, tí ẹ sì ṣọ̀fọ̀ ní oṣù karùn-ún àti keje, àní fun àádọ́rin ọdún wọ̀nyí, ǹjẹ́ èmi ni ẹ̀yin ha ń gbààwẹ̀ yín fún?
6 Na rĩrĩa mwarĩĩaga na mũkanyua-rĩ, githĩ mũtiarĩĩaga ndĩa ĩyo nĩ ũndũ wa inyuĩ ene?
Nígbà tí ẹ sì jẹ, àti nígbà tí ẹ mu, fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin jẹ, àti fún ara yín kọ́ ni ẹ̀yin mú bí?
7 Githĩ ici ticio ciugo cia Jehova iria cianĩrĩirwo igereire harĩ anabii a tene, rĩrĩa Jerusalemu na matũũra marĩa maarĩthiũrũrũkĩirie maarĩ na ũhurũko na makaagaacĩra, nakuo Negevu na hũgũrũrũ-inĩ cia irĩma cia mwena wa ithũĩro nĩ gwatũũragwo nĩ andũ?’”
Wọ̀nyí kọ́ ni ọ̀rọ̀ ti Olúwa ti kígbe láti ọ̀dọ̀ àwọn wòlíì ìṣáájú wá, nígbà tí a ń gbé Jerusalẹmu, tí ó sì wà ní àlàáfíà, pẹ̀lú àwọn ìlú rẹ̀ tí ó yí i káàkiri, nígbà tí a ń gbé gúúsù àti pẹ̀tẹ́lẹ̀.’”
8 Ndũmĩrĩri ya Jehova nĩyakinyĩire Zekaria o rĩngĩ akĩĩrwo atĩrĩ:
Ọ̀rọ̀ Olúwa sì tọ Sekariah wá, wí pé,
9 “Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga ũũ: ‘Tuagai ciira na kĩhooto; iguanagĩrai tha na mũcaayanagĩre mũndũ na ũrĩa ũngĩ.
“Báyìí ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí pé, ‘Ṣe ìdájọ́ òtítọ́, kí ẹ sì ṣe àánú àti ìyọ́nú olúkúlùkù sí arákùnrin rẹ̀.
10 Mũtikanahinyĩrĩrie mũtumia wa ndigwa kana mwana wa ngoriai, kana mũndũ wa kũngĩ, kana mũthĩĩni. Mũtikaneciiranĩrie ũũru ngoro-inĩ cianyu.’
Má sì ṣe ni opó lára tàbí aláìní baba, àlejò, tàbí tálákà; kí ẹnikẹ́ni nínú yín má ṣe gbèrò ibi ní ọkàn sí arákùnrin rẹ̀.’
11 “No nĩmaregire kũigua; makĩngʼathia, na makĩhũgũka na magĩthinga matũ mao.
“Ṣùgbọ́n wọ́n kọ̀ láti gbọ́, wọ́n sì gún èjìká, wọ́n sì pa ẹ̀yìn dà, wọ́n di etí wọn, kí wọn má ba à gbọ́.
12 Nao makĩũmia ngoro ciao o ta ihiga rĩa nyaigĩ, na matingĩathikĩrĩirie watho kana ndũmĩrĩri ĩrĩa Jehova Mwene-Hinya-Wothe aamatũmĩire na Roho wake, aarĩtie na tũnua twa anabii a tene. Nĩ ũndũ ũcio, Jehova Mwene-Hinya-Wothe akĩrakara mũno.
Wọ́n sé ọkàn wọn bí òkúta líle, kí wọn má ba à gbọ́ òfin, àti ọ̀rọ̀ tí Olúwa àwọn ọmọ-ogun ti fi ẹ̀mí rẹ̀ rán nípa ọwọ́ àwọn wòlíì ìṣáájú wá. Ìbínú ńlá sì dé láti ọ̀dọ̀ Olúwa àwọn ọmọ-ogun.
13 “Jehova Mwene-Hinya-Wothe ekuuga atĩrĩ, ‘Rĩrĩa ndeetanire, matiathikĩrĩirie; nĩ ũndũ ũcio rĩrĩa nao maanjĩtire, ndiamathikĩrĩirie.
“‘Ó sì ṣe, gẹ́gẹ́ bí ó ti kígbe, tí wọn kò sì fẹ́ gbọ́, bẹ́ẹ̀ ni wọ́n kígbe, tí èmi kò sì fẹ́ gbọ́,’ ni Olúwa àwọn ọmọ-ogun wí.
14 Nĩndamaharaganirie na kĩhuhũkanio kĩnene ndũrĩrĩ-inĩ ciothe, magĩtũũra kuo marĩ ageni. Bũrũri wao watigirwo ũkirĩte ihooru, na nĩ ũndũ ũcio gũkĩaga mũndũ ũngĩũtuĩkania kana acooke kuo. Ũguo nĩguo maatũmire bũrũri ũcio mwega ũkire ihooru.’”
‘Mo sì fi ìjì tú wọn ká sí gbogbo orílẹ̀-èdè tí wọn kò mọ̀. Ilẹ̀ náà sì dahoro lẹ́yìn wọn, tí ẹnikẹ́ni kò là á kọjá tàbí kí ó padà bọ̀, wọ́n sì sọ ilẹ̀ ààyò náà dahoro.’”