< Thaburi 95 >

1 Ũkai, tũinĩre Jehova nĩ gũkena; tũkĩanĩrĩre ũcio Rwaro rwa Ihiga rwa ũhonokio witũ.
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a kọ orin ayọ̀ sí Olúwa, ẹ jẹ́ kí a kígbe sókè sí àpáta ìgbàlà wa.
2 Nĩtũũkei mbere yake tũgĩcookagia ngaatho, na tũmũinĩre nyĩmbo cia kũmũkumia.
Ẹ jẹ́ kí a wá sí iwájú rẹ̀ pẹ̀lú ọpẹ́ kí a sì pòkìkí rẹ̀ pẹ̀lú ohun èlò orin àti ìyìn.
3 Nĩgũkorwo Jehova nĩ Mũrungu mũnene, o we Mũthamaki mũnene ũkĩrĩte ngai ciothe.
Nítorí Olúwa Ọlọ́run títóbi ni, ọba tí ó tóbi ju gbogbo òrìṣà lọ.
4 Thĩ kũrĩa kũriku mũno kũrĩ guoko-inĩ gwake, o na tũcũmbĩrĩ twa irĩma no twake.
Ní ọwọ́ rẹ̀ ni ọ̀gbun ilẹ̀ wà, ṣóńṣó orí òkè tirẹ̀ ní ṣe.
5 Iria nĩ rĩake, nĩgũkorwo nĩwe warĩũmbire, na moko make nĩmo moombire thĩ nyũmũ.
Tirẹ̀ ni Òkun, nítorí òun ni ó dá a àti ọwọ́ rẹ̀ ni ó fi dá ìyàngbẹ ilẹ̀.
6 Ũkai, tũmũinamĩrĩre tũmũhooe, nĩtũturĩrie Jehova o we Mũtũũmbi ndu;
Ẹ wá, ẹ jẹ́ kí a foríbalẹ̀ kí a sìn ín, ẹ jẹ́ kí a kúnlẹ̀ níwájú Olúwa ẹni tí ó dá wa,
7 nĩgũkorwo nĩwe Ngai witũ, na ithuĩ tũrĩ andũ a ũrĩithio wake, rũũru rũrĩa we mwene arĩithagia. Ũmũthĩ mũngĩigua mũgambo wake,
nítorí òun ni Ọlọ́run wa, àwa sì ni ènìyàn pápá rẹ̀, àti ọ̀wọ́ ẹran ni abẹ́ ìpamọ́ rẹ̀. Lónìí tí ìwọ bá gbọ́ ohùn rẹ̀,
8 mũtikoomie ngoro cianyu ta ũrĩa mwekire mũrĩ Meriba, o na ta ũrĩa mwekire mũthenya ũrĩa mwarĩ Masa kũu werũ-inĩ,
“Ẹ má ṣe sé ọkàn yín le gẹ́gẹ́ bí ẹ ti ṣe ní Meriba, àti bí ẹ ti ṣe ní ọjọ́ náà ní Massa ní aginjù,
9 kũrĩa maithe manyu maangeririe na makĩngararia, o na gũtuĩka nĩmoonete ũrĩa wothe ndaamekĩire.
nígbà tí àwọn baba yín dán mi wò tí wọn wádìí mi, tí wọn sì rí iṣẹ́ mi.
10 Nĩgũkorwo ndaatũũrĩte ndakarĩire rũciaro rũu mĩaka mĩrongo ĩna; ngiuga atĩrĩ, “Aya nĩ andũ arĩa ngoro ciao ciũrĩte, na nĩmagĩte kũmenya njĩra ciakwa.”
Fún ogójì ọdún ni èmi fi bínú sí ìran náà; mo wí pé, ‘Wọ́n jẹ́ ènìyàn tí ọkàn wọn ṣáko lọ wọn kò sì mọ ọ̀nà mi.’
11 Nĩ ũndũ ũcio ngĩĩhĩta ndakarĩte, ngiuga atĩrĩ, “Matirĩ hĩndĩ magaatoonya kĩhurũko-inĩ gĩakwa.”
Nítorí náà ni mo kéde ìbúra nínú ìbínú mi, ‘Wọn kì yóò wọ ibi ìsinmi mi.’”

< Thaburi 95 >