< Thaburi 89 >
1 Thaburi ya Ethani wa mbarĩ ya Ezara Ngũtũũra nyinaga ũhoro wa wendo mũnene wa Jehova nginya tene; ndĩrĩmenyithanagia wĩhokeku waku na kanua gakwa kũrĩ njiarwa na njiarwa.
Maskili ti Etani ará Esra. Èmi kọrin títóbi ìfẹ́ Olúwa títí láé; pẹ̀lú ẹnu mi ní èmi yóò jẹ́ kí a mọ òtítọ́ rẹ láti ìran dé ìran.
2 Nĩngumbũra atĩ wendo waku ũtũũraga ũrĩ mũrũmu nginya tene, nyumbũre atĩ wĩhokeku waku nĩũũhaandĩte o kũu igũrũ.
Èmi ó wí pé, ìfẹ́ rẹ dúró títí láé, pé ìwọ gbe òtítọ́ rẹ kalẹ̀ ní ọ̀run fúnra rẹ̀.
3 Woigire atĩrĩ, “Nĩngĩte kĩrĩkanĩro na ũrĩa niĩ ndĩthuurĩire, na ngeehĩta na mwĩhĩtwa harĩ Daudi ndungata yakwa ngamwĩra atĩrĩ,
Ìwọ wí pé, “Èmi ti dá májẹ̀mú pẹ̀lú àwọn àyànfẹ́ mi mo ti búra fún Dafidi ìránṣẹ́ mi.
4 ‘Nĩngatũma rũciaro rwaku rũtũũre rwĩhaandĩte nginya tene, na ndũme gĩtĩ gĩaku kĩa ũnene gĩtũũre kĩrĩ kĩrũmu njiarwa na njiarwa.’”
‘Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ múlẹ̀ títí láé èmí ó sì máa gbe ìtẹ́ rẹ ró láti ìran dé ìran.’”
5 Wee Jehova-rĩ, igũrũ nĩrĩkumagia magegania maku, na rĩkagaathĩrĩria wĩhokeku waku o naguo, kĩũngano-inĩ kĩa acio atheru.
Àwọn ọ̀run yóò máa yin iṣẹ́ ìyanu rẹ, Olúwa, òtítọ́ rẹ ni ìpéjọpọ̀ àwọn ẹni mímọ́.
6 Nĩ ũndũ-rĩ, kũu matu-inĩ igũrũ nũũ ũngĩgerekanio na Jehova? Nũũ ũkĩhaana ta Jehova harĩ ciũmbe iria irĩ igũrũ?
Ta ni ó wà ní ọ̀run tí a lè fiwé Olúwa? Ta ni nínú àwọn ọmọ alágbára ti a lè fiwé Olúwa?
7 Kĩama-inĩ kĩa acio atheru, Mũrungu nĩetigĩrĩtwo mũno; nĩ wa gwĩtigĩrwo gũkĩra arĩa othe mamũrigiicĩirie.
Nínú àjọ ìgbìmọ̀ ẹni mímọ́, wọ́n bẹ̀rù Ọlọ́run gidigidi; ó sì ní ìbùyìn fún ju gbogbo àwọn tí ó yí i ká.
8 Wee Jehova Ngai Mwene-Hinya-Wothe, nũũ ũkĩhaana tawe? Wee Jehova, nĩ ũrĩ hinya, na wĩhokeku waku ũtũũraga ũkũrigiicĩirie.
Olúwa Ọlọ́run alágbára, ta ló dàbí rẹ ìwọ jẹ́ alágbára, Olúwa, òtítọ́ rẹ sì yí ọ ká.
9 Nĩwe wathaga kĩhuhũkanio kĩa iria rĩrĩa inene; rĩrĩa makũmbĩ marĩo mookĩra na igũrũ, nĩũmahooreragia.
Ìwọ ń darí ríru omi Òkun; nígbà tí ó ru àwọn omi sókè, ìwọ mú wọn parọ́rọ́.
10 Wahehenjire Rahabu agĩtuĩka o ta ũmwe wa arĩa moragĩtwo; wahurunjire thũ ciaku na guoko gwaku kũrĩ hinya.
Ìwọ ni ó ti ya Rahabu pẹ́rẹpẹ̀rẹ bí ẹni tí a pa; ìwọ ti fi apá ọwọ́ agbára rẹ tú àwọn ọ̀tá rẹ ká.
11 Igũrũ nĩ rĩaku, o na thĩ no yaku; Wee nĩwe wombire thĩ na kĩrĩa gĩothe kĩrĩ thĩinĩ wayo.
Tìrẹ ní àwọn ọ̀run, ayé pẹ̀lú jẹ́ tìrẹ: ayé àti ohun gbogbo tí ó wà nínú rẹ̀: ìwọ ti gbé wọn kalẹ̀.
12 Nĩwe wombire mwena wa gathigathini na wa gũthini; Taboru na Herimoni ciinaga ikenete nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩaku.
Gúúsù àti àríwá ìwọ ni ó dá wọn; Tabori àti Hermoni ń fi ayọ̀ yin orúkọ rẹ.
13 Gĩcoka gĩaku nĩ kĩrĩ ũhoti; guoko gwaku kũrĩ hinya, guoko gwaku kwa ũrĩo nĩgũtũgĩrie.
Ìwọ ní apá agbára; agbára ní ọwọ́ rẹ, gíga ní ọwọ́ ọ̀tún rẹ.
14 Ũthingu na kĩhooto nĩcio mũthingi wa gĩtĩ gĩaku kĩa ũnene; wendo na wĩhokeku nĩigũtongoragia.
Òdodo àti òtítọ́ ni ìpìlẹ̀ ìtẹ́ rẹ: ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ àti òtítọ́ ń lọ síwájú rẹ.
15 Kũrathimwo-rĩ, nĩ andũ arĩa mooĩ gũkũgooca na nyĩmbo, o arĩa mathiiaga na ũtheri waku, Wee Jehova.
Ìbùkún ni fún àwọn ènìyàn tí wọn mọ ohùn ayọ̀ nì, Olúwa wọ́n ó máa rìn ní ìmọ́lẹ̀ ojú rẹ.
16 Makenagĩra rĩĩtwa rĩaku mũthenya wothe; magũtũũgagĩria nĩ ũndũ wa ũthingu waku.
Wọn ń ṣògo nínú orúkọ rẹ̀ ní gbogbo ọjọ́, wọn ń yin òdodo rẹ.
17 Nĩgũkorwo Wee nĩwe riiri na hinya wao, na tondũ wa ũtugi waku nĩũtũũgagĩria rũhĩa rwitũ.
Nítorí ìwọ ni ògo agbára wọn; nípa ojúrere ni ìwo wá ń ṣògo.
18 Ti-itherũ, ngo iitũ ĩrĩ na Jehova, mũthamaki witũ nĩ wa Ũrĩa-Mũtheru-wa-Isiraeli.
Nítorí ti Olúwa ni asà wa, ọba wa sì ni Ẹni Mímọ́ Israẹli.
19 Hĩndĩ ĩmwe nĩwaririe na njĩra ya kĩoneki, ũkĩĩra andũ aku arĩa ehokeku atĩrĩ, “Nĩheete njamba ĩmwe ya ita hinya; nĩndũgĩrĩtie mwanake gatagatĩ ka andũ.
Nígbà náà ni ìwọ sọ̀rọ̀ nínú ìran, sí àwọn olóòtítọ́ rẹ, wí pé, “Èmi ti gbé adé kalẹ̀ sórí ẹni tí ó lágbára, èmi ti gbé ẹni tí a yàn láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn ga.
20 Nĩndĩĩoneire Daudi ndungata yakwa; nĩndĩmũitĩrĩirie maguta makwa maamũre.
Èmi ti rí Dafidi ìránṣẹ́ mi; pẹ̀lú òróró mímọ́ mi ni mo fi yàn án.
21 Guoko gwakwa nĩkũrĩmũtiiragĩrĩra; ti-itherũ gĩcoka gĩakwa nĩkĩrĩmwĩkagĩra hinya.
Ìgbà gbogbo ni ọwọ́ mi yóò máa wà pẹ̀lú rẹ̀ apá mí yóò sì fi agbára fún un.
22 Gũtirĩ thũ ĩkaamwĩtia igooti. gũtirĩ mũndũ mwaganu ũkaamũhinyĩrĩria.
Àwọn ọ̀tá kì yóò borí rẹ̀, àwọn ènìyàn búburú kì yóò rẹ̀ ẹ́ sílẹ̀.
23 Nĩngahehenja thũ ciake mbere yake, na njũrage arĩa othe mamũthũire.
Èmi yóò run àwọn ọ̀tá rẹ níwájú rẹ èmi yóò lu àwọn tí ó kórìíra rẹ bolẹ̀.
24 Wendo wakwa wa kwĩhokeka ũrĩkoragwo hamwe nake, na nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩakwa rũhĩa rwake nĩrũrĩtũũgagĩrio.
Òtítọ́ mi àti ìdúró ṣinṣin ìfẹ́ yóò wà pẹ̀lú rẹ àti ní orúkọ mi ni a ó gbé ìwo rẹ ga.
25 Nĩngatambũrũkia guoko gwake igũrũ rĩa iria, na guoko gwake kwa ũrĩo ndĩkũige igũrũ rĩa njũũĩ.
Èmi ó gbé ọwọ́ rẹ lórí òkun, àti ọwọ́ ọ̀tún rẹ lórí àwọn odo ńlá.
26 Nĩakanjĩta anjĩĩre atĩrĩ, ‘Wee nĩwe Baba, na Mũrungu wakwa, o Rwaro rwa Ihiga, Mũhonokia wakwa.’
Òun yóò kígbe sí mi pé, ‘Ìwọ ni baba mi, Ọlọ́run mi, àti àpáta ìgbàlà mi!’
27 Ningĩ nĩngamwamũra atuĩke irigithathi rĩakwa, na ndũme atũũgĩrio gũkĩra athamaki a thĩ.
Èmi yóò ṣe é ni àkọ́bí mi, ẹni gíga ju àwọn ọba ayé.
28 Nĩngũtũũria wendo wakwa harĩ we nginya tene, na kĩrĩkanĩro gĩakwa nake gĩtũũre kĩrĩ gĩa kwĩhokeka.
Títí láé ni èmi yóò pa ìfẹ́ dídúró ṣinṣin mọ́ fún un, àti májẹ̀mú mi pẹ̀lú rẹ̀ yóò dúró gbọingbọin.
29 Nĩngahaanda rũciaro rwake nginya tene, na gĩtĩ gĩake kĩa ũnene ndĩkĩhaande rĩrĩa rĩothe igũrũ rĩgũtũũra.
Èmi ó fi ìdí irú-ọmọ rẹ̀ múlẹ̀ títí láé, àti ìtẹ́ rẹ gẹ́gẹ́ bí ọ̀run ti wà láé.
30 “Ariũ ake mangĩgatirika watho wakwa na mage kũrũmĩrĩra kĩrĩra gĩakwa,
“Bí àwọn ọmọ rẹ̀ bá kọ òfin mi sílẹ̀ tí wọn kò sì rìn gẹ́gẹ́ bí ìlànà mi.
31 mangĩgathũkia kĩrĩra kĩa watho wakwa wa kũrũmĩrĩrwo na mage kũmenyerera maathani makwa,
Tí wọn bá ba ìlànà mi jẹ́ tí wọn kò sì pa àṣẹ mi mọ́,
32 nĩngaherithia wĩhia wao na rũthanju, herithie waganu wao na kũmahũũra iboko;
nígbà náà ni èmi ó fì ọ̀gọ̀ bẹ ìrékọjá wọn wò; àti ẹ̀ṣẹ̀ wọn pẹ̀lú pàṣán;
33 no ndirĩ hĩndĩ ngaamwehereria wendo wakwa, o na kana thaahie wĩhokeku wakwa o na rĩ.
ṣùgbọ́n èmi kò ní mú ìfẹ́ mi tí ó dúró ṣinṣin kúrò lọ́dọ̀ rẹ, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò jẹ́ kí òtítọ́ mi kí ó yẹ̀.
34 Ndigathũkia kĩrĩkanĩro gĩakwa kana ngarũrĩre ũrĩa iromo ciakwa ciarĩtie.
Èmi kì yóò sẹ́ májẹ̀mú mi, bẹ́ẹ̀ ni èmi kì yóò yí ọ̀rọ̀ tí ó ti ẹnu mi jáde padà.
35 Nĩndĩhĩtĩte ngĩgwetaga ũtheru wakwa, rĩmwe rĩa kũigana, na ndirĩ hĩndĩ ngaaheenia Daudi,
Lẹ́ẹ̀kan ṣoṣo ni èmi ti fi ìwà mímọ́ mi búra; èmi kì yóò purọ́ fún Dafidi.
36 atĩ rũciaro rwake rũgũtũũra nginya tene, na gĩtĩ gĩake kĩa ũnene gĩtũũre kĩrĩ kĩrũmu mbere yakwa ta riũa;
Irú-ọmọ rẹ yóò dúró títí láé, àti ìtẹ́ rẹ̀ yóò dúró bí oòrùn níwájú mi.
37 gĩgũtũũra kĩrĩ kĩrũmu nginya tene o ta mweri, mũira ũrĩa ũrĩ matu-inĩ nĩ mwĩhokeku.”
A ó fi múlẹ̀ títí láé bí òṣùpá, àti bi ẹlẹ́rìí òtítọ́ ni ọ̀run.” (Sela)
38 No rĩrĩ, wee nĩũregete, na ũgatiganĩria, o na ũgakĩrakarĩra ũcio ũitĩrĩirie maguta.
Ṣùgbọ́n nísinsin yìí ìwọ ti ṣá tì, ìwọ sì kórìíra; ìwọ kún fún ìrunú sí ẹni àmì òróró rẹ.
39 Wee nĩũkanĩte kĩrĩkanĩro kĩrĩa ũrĩkanĩire na ndungata yaku, na ũkarangĩrĩria thũmbĩ yake rũkũngũ-inĩ.
Ìwọ ti sọ májẹ̀mú ìránṣẹ́ rẹ di òfo; ìwọ tàbùkù adé rẹ nínú eruku.
40 Wee ũmomorete thingo ciake ciothe na ũkaananga ciĩhitho ciake iria cia hinya.
Ìwọ ti wó gbogbo àwọn odi rẹ̀ ìwọ sọ ibi gíga rẹ̀ di ahoro.
41 Ehĩtũkĩri othe nĩmatahĩte indo ciake; atuĩkĩte wa kũnyararwo nĩ andũ arĩa mariganĩtie nake.
Àwọn tí ń kọjá lọ fi ṣe ìjẹ; ó ti di ẹ̀gàn àwọn olùbágbé rẹ̀.
42 Wee nĩũtũũgĩrĩtie guoko kwa ũrĩo kwa arĩa mamũthũire; nĩũtũmĩte thũ ciake ciothe ikene.
Ìwọ ti gbé ọwọ́ ọ̀tún ọ̀tá rẹ̀ sókè; ìwọ mú gbogbo ọ̀tá rẹ̀ yọ̀.
43 Ũũgĩ wa rũhiũ rwake rwa njora nĩũũhũndũrĩte, na ũkaaga kũmũteithĩrĩria mbaara-inĩ.
Pẹ̀lú, ìwọ ti yí ojú idà rẹ̀ padà, ìwọ kò sì dúró tì í nínú ogun.
44 Nĩũniinĩte riiri wake ũgathira, na ũgaikania gĩtĩ gĩake kĩa ũnene thĩ.
Ìwọ ti mú ògo rẹ̀ kùnà, ìwọ si wó ìtẹ́ rẹ̀ palẹ̀ sílẹ̀ẹ́lẹ̀.
45 Nĩũnyiihĩtie matukũ ma wĩthĩ wake; ũmũhumbĩte thoni o ta nguo.
Ìwọ ti gé ọjọ́ èwe rẹ̀ kúrú; ìwọ sì fi ìtìjú bò ó.
46 Nĩ nginya rĩ, Wee Jehova? Ũgũtũũra wĩhithĩte nginya tene? Nĩ nginya rĩ mangʼũrĩ maku megũtũũra maakanĩte ta mwaki?
Yóò ti pẹ́ tó, Olúwa? Tí ìwọ ó ha fi ara rẹ pamọ́ títí láé? Yóò ti pẹ́ to tí ìbínú rẹ yóò máa jó bí iná?
47 Ririkana ũrĩa mũtũũrĩre wakwa ũrĩ wa gũthira o narua. Kaĩ akĩrĩ ũndũ wa tũhũ watũmire ũmbe andũ othe!
Rántí bí ọjọ́ mi ti kúrú tó nítorí asán ha ni ìwọ fi ṣẹ̀dá àwọn ènìyàn!
48 Nĩ mũndũ ũrĩkũ ũngĩtũũra muoyo na ndonane na gĩkuũ, kana ehonokie kuuma kũrĩ hinya wa mbĩrĩra? (Sheol )
Ta ni yóò wà láààyè tí kò ní rí ikú rẹ̀? Ta ló lè sá kúrò nínú agbára isà òkú? (Sheol )
49 Wee Mwathani, wendo waku mũnene ũrĩa wa tene ũkĩrĩ kũ, ũrĩa wehĩtire, ũkĩĩrĩra Daudi na ũndũ wa wĩhokeku waku?
Olúwa, níbo ni ìṣeun ìfẹ́ rẹ àtijọ́ wà, tí ìwọ ti fi òtítọ́ rẹ búra fún Dafidi?
50 Mwathani, ririkana ũrĩa ndungata yaku ĩnyũrũrĩtio, na ũrĩa nyũmĩrĩirie irumi iria numĩtwo nĩ ndũrĩrĩ ciothe ngoro-inĩ yakwa,
Rántí, Olúwa, bí a ti ń gan àwọn ìránṣẹ́ rẹ; bí èmi ti gbà ní àyà mi láti ọ̀dọ̀ àwọn ènìyàn,
51 o irumi iria thũ ciaku iinyũrũrĩtie nacio, Wee Jehova, iria itũire inyũrũrĩtie makinya ma ũrĩa wee ũitĩrĩirie maguta nacio.
ẹ̀gàn tí àwọn ọ̀tá rẹ gàn, Olúwa, tí wọn gan ipasẹ̀ ẹni àmì òróró rẹ.
52 Jehova arogoocwo nginya tene!
Olùbùkún ní Olúwa títí láé.