< Thaburi 81 >

1 Thaburi ya Asafu Inĩrai Ngai, o we hinya witũ, nĩ ũndũ wa gũkena; anĩrĩrai mũinĩre Ngai wa Jakubu!
Fún adarí orin. Gẹ́gẹ́ bí ti gittiti. Ti Asafu. Kọrin sókè sí Ọlọ́run agbára wa ẹ hó ìhó ayọ̀ sí Ọlọ́run Jakọbu!
2 Ambĩrĩriai kũina, hũũrai kĩhembe, na mũhũũre kĩnanda kĩa mũgeeto kĩrĩa kĩgambi wega, o na gĩa kĩnũbi.
Ẹ mú orin mímọ́, kí ẹ sì mú ìlù wá, tẹ dùùrù dídùn pẹ̀lú ohun èlò orin mímọ́.
3 Huhai coro hĩndĩ ya Karũgamo ka Mweri, na ningĩ rĩrĩa mweri waiganana, mũthenya ũrĩa wa Gĩathĩ giitũ;
Ẹ fún ìpè ní oṣù tuntun àní nígbà tí a yàn; ní ọjọ́ àjọ wa tí ó ní ìrònú.
4 ũyũ nĩ watho wa kĩrĩra gĩa kũrũmĩrĩrwo kũrĩ Isiraeli, o guo watho wa Ngai wa Jakubu.
Èyí ni àṣẹ fún Israẹli, àti òfin Ọlọ́run Jakọbu.
5 We nĩaũhaandire ũtuĩke kĩrĩra harĩ Jusufu hĩndĩ ĩrĩa aathiire gũtharĩkĩra bũrũri wa Misiri, kũrĩa twaiguire mwario tũtaamenyire.
Ó fi múlẹ̀ gẹ́gẹ́ bí ìlànà fún Josẹfu nígbà tí ó la ilẹ̀ Ejibiti já. Níbi tí a ti gbọ́ èdè tí kò yé wa.
6 Ekuuga atĩrĩ, “Nĩndeheririe mũrigo kuuma ciande-inĩ ciao; moko mao nĩndameheririe kuuma thĩinĩ wa gĩkabũ.
Ó wí pé, “Mo gbé àjàgà kúrò ní èjìká yín, a tú ọwọ́ wọn sílẹ̀ kúrò nínú apẹ̀rẹ̀.
7 Wangaĩire ũrĩ na mĩnyamaro na niĩ ngĩkũhatũra, ngĩgwĩtĩka ndĩ thĩinĩ wa mũrurumo wa ngwa; ndakũgeririe ũrĩ kũu maaĩ-inĩ ma Meriba.
Nínú ìnilára ni ẹ pè mo sì gbà yín là, mo dá a yín lóhùn nínú ìkọ̀kọ̀ àrá, mo dán an yín wò ní odò Meriba. (Sela)
8 “Inyuĩ andũ akwa, iguai ngĩmũkaania, naarĩ korwo no mũũthikĩrĩrie, inyuĩ Isiraeli!
“Gbọ́, ẹ̀yin ènìyàn mi, èmi ó sì kìlọ̀ fún un yín, bí ìwọ bá fetí sí mi, ìwọ Israẹli.
9 Mũtikanagĩe na ngai ngʼeni gatagatĩ-inĩ kanyu; mũtikanainamĩrĩre ngai ya kũngĩ.
Ẹ̀yin kì yóò ní Ọlọ́run ilẹ̀ mìíràn láàrín yín; ẹ̀yin kì yóò foríbalẹ̀ fún Ọlọ́run àjèjì.
10 Nĩ niĩ Jehova Ngai waku, ũrĩa wakũrutire bũrũri wa Misiri. Athamia kanua gaku na nĩngũkũhe gĩa kũrĩa.
Èmi ni Olúwa Ọlọ́run rẹ, ẹni tí ó mú un yín jáde láti Ejibiti. Ẹ la ẹnu yín gbòòrò, èmi yóò sì kún un.
11 “No andũ akwa matiigana gũũthikĩrĩria; Isiraeli ndaigana kũnjathĩkĩra.
“Ṣùgbọ́n àwọn ènìyàn mi kì yóò gbọ́ tèmi; Israẹli kò ní tẹríba fún mi.
12 Nĩ ũndũ ũcio ngĩmarekereria marũmĩrĩre ũremi wa ngoro ciao, na marũmagĩrĩre mwĩĩro wao ene.
Nítorí náà ni mo ṣe fi wọ́n fún ọkàn líle wọn láti máa rìn ní ọ̀nà ẹ̀tàn wọn.
13 “Korwo andũ akwa no maathikĩrĩrie, korwo Isiraeli no marũmĩrĩre njĩra ciakwa,
“Bí àwọn ènìyàn mi yóò bá gbọ́ tèmi bí Israẹli yóò bá tẹ̀lé ọ̀nà mi,
14 ndamatooreria thũ ciao o na ihenya, na njũkĩrĩre andũ arĩa marĩ muku nao na ũndũ wa guoko gwakwa!
ní kánkán ni èmi yóò ṣẹ́gun àwọn ọ̀tá wọn kí n sì yí ọwọ́ mi padà sí ọ̀tá wọn!
15 Andũ arĩa mathũire Jehova mangĩĩthuna marĩ mbere yake, na iherithia rĩao rĩtũũre nginya tene.
Àwọn tí ó kórìíra Olúwa yóò tẹríba níwájú rẹ̀. Ìjìyà wọn yóò sì pẹ́ títí láé.
16 No inyuĩ ingĩmũhe ngano ĩrĩa njega mũno mũrĩĩage; ingĩmũhũũnagia na ũũkĩ wa kuuma rwaro-inĩ rwa ihiga.”
Ṣùgbọ́n a ó fi ọkà tí ó dára bọ́ ọ yín èmi ó tẹ́ ẹ yín lọ́rùn pẹ̀lú oyin inú àpáta.”

< Thaburi 81 >