< Thaburi 41 >
1 Thaburi ya Daudi Kũrathimwo-rĩ, nĩ mũndũ ũrĩa ũrũmbũyagia andũ arĩa matarĩ hinya; ũcio-rĩ, Jehova nĩamũhatũraga hĩndĩ ya mathĩĩna.
Fún adarí orin. Saamu Dafidi. Ìbùkún ni fún ẹni tí ó ń ro ti aláìní: Olúwa yóò gbà á ní ìgbà ìpọ́njú.
2 Jehova nĩarĩmũgitagĩra na amũtũũragie muoyo; nĩarĩmũrathimaga bũrũri-inĩ, na ndakamũrekereria kũrĩ merirĩria ma thũ ciake.
Olúwa yóò dáàbò bò ó yóò sì pa ọkàn rẹ̀ mọ́: yóò bùkún fún un ní orí ilẹ̀ kò sì ní fi sílẹ̀ fún ìfẹ́ àwọn ọ̀tá rẹ̀.
3 Jehova nĩarĩmũmenyagĩrĩra arĩ ũrĩrĩ-inĩ arĩ mũrũaru, na acooke amũhonie arĩ o hau ũrĩrĩ-inĩ wake.
Olúwa yóò gbà á lórí àkéte àìsàn rẹ̀ yóò sì mú un padà bọ̀ sípò kúrò nínú àìsàn rẹ̀.
4 Ndoigire atĩrĩ, “Wee Jehova, njiguĩra tha; honia, nĩgũkorwo Wee nĩwe njĩhĩirie.”
Ní ti èmi, mo wí pé “Olúwa, ṣàánú fún mi; wò mí sàn, nítorí pé mo ti ṣẹ̀ sí ọ”.
5 Thũ ciakwa ciaragia ũhoro wakwa na rũmena ikooria atĩrĩ, “Agakua rĩ, rĩĩtwa rĩake rĩthire?”
Àwọn ọ̀tá mi ń sọ̀rọ̀ mi nínú àrankàn, pé, “Nígbà wo ni yóò kú, ti orúkọ rẹ̀ yóò sì run?”
6 Rĩrĩa rĩothe mũndũ ooka kũnyona, aaheaga ũhoro wa maheeni, o rĩrĩa ngoro yake ĩrahũnga ndeto cia kũnjambia; agacooka agathiĩ gũcimemeerekia kũndũ guothe.
Nígbàkígbà tí ẹnìkan bá wá wò mí, wọn ń sọ̀rọ̀ ẹ̀tàn, nígbà tí àyà rẹ̀ bá kó ẹ̀ṣẹ̀ jọ sí ara rẹ̀; nígbà tí ó bá jáde lọ yóò sì máa tàn án kálẹ̀.
7 Thũ ciakwa ciothe iheehanagĩra nĩguo iinjũkĩrĩre; injiiragĩrĩra maũndũ mooru mũno, ikoiga atĩrĩ,
Àwọn ọ̀tá mi gbìmọ̀ papọ̀ nípa mi; èmi ni wọ́n ń gbìmọ̀ ibi sí,
8 “Mũrimũ mũũru nĩũmũnyiitĩte; ndarĩ hĩndĩ agokĩra hau akomete.”
wọ́n wí pé, “Ohun búburú ni ó dì mọ́ ọn ṣinṣin àti ní ibi tí ó dùbúlẹ̀ sí, kì yóò dìde mọ́.”
9 O na mũrata wakwa wa hakuhĩ, ũrĩa ndĩrehokete, o ũrĩa tũrĩĩanagĩra irio nake nĩangarũrũkĩte.
Pàápàá, ọ̀rẹ́ mi tímọ́tímọ́, ẹni tí mo gbẹ́kẹ̀lé, ẹni tí ó ń jẹ nínú oúnjẹ mi, tí gbé gìgísẹ̀ rẹ̀ sókè sí mi.
10 No rĩrĩ, Wee Jehova, njiguĩra tha; njarahũra, nĩguo ndĩĩrĩhĩrie harĩo.
Ṣùgbọ́n ìwọ Olúwa, ṣàánú fún mi; gbé mi sókè, kí ń ba lè san fún wọn.
11 Nĩnjũũĩ atĩ nĩũkenetio nĩ niĩ, nĩgũkorwo thũ yakwa ndĩndooretie.
Èmi mọ̀ pé inú rẹ̀ dùn sí mi, nítorí ọ̀tá mi kò borí mi.
12 We nĩũũnyiitĩrĩire nĩ ũndũ wa wagĩrĩru wakwa, na ũkanjiga harĩwe nginya tene.
Bí ó ṣe tèmi ni ìwọ dì mímú nínú ìwà òtítọ́ mi ìwọ sì gbé mi kalẹ̀ níwájú rẹ títí láé.
13 Jehova, o we Ngai wa Isiraeli, arogoocwo, kuuma tene wa tene nginya tene na tene. Ameni, na ningĩ Ameni.
Olùbùkún ni Olúwa, Ọlọ́run Israẹli, láé àti láéláé.