< Thaburi 4 >
1 Thaburi ya Daudi Njĩtĩka rĩrĩa ndagũkaĩra, Wee Ngai wakwa, o Wee mũthingu. Ũndeithagie rĩrĩa ndĩ mĩnyamaro-inĩ; njiguĩra tha na ũigue mahooya makwa.
Fún adarí orin. Pẹ̀lú ohun èlò orin olókùn. Saamu ti Dafidi. Dá mi lóhùn nígbà tí mo bá pè ọ́, ìwọ Ọlọ́run òdodo mi. Fún mi ní ìdáǹdè nínú ìpọ́njú mi; ṣàánú fún mi, kí o sì gbọ́ àdúrà mi.
2 Inyuĩ, andũ aya, nĩ nginya rĩ mũgũtũũra mũtũmaga riiri wakwa ũnyararwo? Nĩ nginya rĩ mũgũtũũra mwendete maũndũ ma tũhũ, na mũkarongoragia ngai cia maheeni?
Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, ẹ̀yin ọmọ ènìyàn, tí ẹ ó ṣe sọ ògo mi di ìtìjú? Báwo ni yóò ṣe pẹ́ tó, tí ẹ̀yin yóò ṣe fẹ́ràn ìtànjẹ àti tí ẹ̀yin yóò fi máa wá ọlọ́run èké?
3 Menyai atĩ Jehova nĩeyamũrĩire arĩa mamwendete; Jehova nĩarĩiguaga rĩrĩa ndamũkaĩra.
Ṣùgbọ́n kí ẹ mọ̀ pé, Olúwa ti ya ẹni olódodo sọ́tọ̀ fún ara rẹ̀; Olúwa yóò gbọ́ nígbà tí mo bá pè é.
4 Mũngĩrakara mũtikehie; rĩrĩa mũrĩ marĩrĩ-inĩ manyu-rĩ, thuthuuragiai ngoro cianyu mwĩkirĩire.
Ẹ bínú ẹ má ṣe ṣẹ̀, nígbà tí ẹ bá wà lórí ibùsùn yín, ẹ bá ọkàn yín sọ̀rọ̀, kí ó sì dákẹ́ jẹ́.
5 Rutagai magongona marĩa magĩrĩire, na mwĩhokage Jehova.
Ẹ rú ẹbọ òdodo kí ẹ sì gbẹ́kẹ̀lé Olúwa.
6 Kũrĩ andũ aingĩ maroria atĩrĩ, “Nũũ ũngĩtuonia maũndũ mega?” Wee Jehova reke ũtheri wa gĩthiithi gĩaku ũtwarĩre.
Ọ̀pọ̀lọpọ̀ ló ń béèrè pé, “Ta ni yóò ṣe rere fún wa?” Olúwa, jẹ́ kí ojú rẹ mọ́lẹ̀ sí wa lára,
7 Wee nĩũnjiyũrĩtie gĩkeno kĩnene ngoro-inĩ yakwa, gũkĩra kĩrĩa makoragwo nakĩo hĩndĩ ya bũthi wa ngano na ndibei ya mũhihano.
Ìwọ ti fi ayọ̀ púpọ̀ kún ọkàn mi ju ìgbà tí hóró irúgbìn àti wáìnì tuntun wọ́n pọ̀ fún mi lọ.
8 Niĩ ndĩrĩkomaga na nyonage toro ndĩ na thayũ, nĩgũkorwo Wee Jehova nĩwe ũikaraga ũũmenyereire wega.
Èmi yóò dùbúlẹ̀, èmi ó sì sùn ní àlàáfíà, nítorí ìwọ nìkan, Olúwa, ni o mú mi gbé láìléwu.