< Thaburi 23 >
1 Thaburi ya Daudi Jehova nĩwe mũrĩithi wakwa, ndirĩ kĩndũ ingĩaga.
Saamu ti Dafidi. Olúwa ni olùṣọ́ èmi àgùntàn rẹ̀, èmi kì yóò ṣe aláìní.
2 Atũmaga njarahe ũrĩithio-inĩ ũrĩ nyeki nduru, aandongoragia maaĩ-inĩ marĩ na ũhurũko.
Ó mú mi dùbúlẹ̀ sí ibi pápá oko tútù, Ó mú mi lọ sí ibi omi dídákẹ́ rọ́rọ́,
3 Nĩariũkagia ngoro yakwa, akandongoragia njĩra-inĩ cia ũthingu, nĩ ũndũ wa rĩĩtwa rĩake.
Ó mú ọkàn mi padà bọ̀ sípò. Ó mú mi lọ sí ọ̀nà òdodo nítorí orúkọ rẹ̀.
4 O na ingĩtuĩka ndĩrahungurĩra mũkuru ũrĩ nduma ta ya gĩkuũ, ndirĩ ũũru ingĩĩtigĩra, nĩgũkorwo ũrĩ hamwe na niĩ; thiarĩ waku na mũthĩgi waku nĩciihooreragia.
Bí mo tilẹ̀ ń rìn láàrín àfonífojì òjìji ikú, èmi kì yóò bẹ̀rù ibi kan, nítorí ìwọ wà pẹ̀lú mi; ọ̀gọ rẹ àti ọ̀pá à rẹ, wọ́n ń tù mí nínú.
5 Ũnjaragĩra metha mbere yakwa o harĩa thũ ciakwa irĩ. Ũnjitagĩrĩria maguta mũtwe; gĩkombe gĩakwa nĩkĩiyũrĩrĩire.
Ìwọ tẹ́ tábìlì oúnjẹ sílẹ̀ níwájú mi ní ojú àwọn ọ̀tá à mi. Ìwọ ta òróró sí mi ní orí; ago mí sì kún àkúnwọ́sílẹ̀.
6 Ti-itherũ wega na wendani nĩirĩrũmanagĩrĩra na niĩ matukũ mothe ma muoyo wakwa, na niĩ ngũtũũra nyũmba ya Jehova nginya tene.
Nítòótọ́, ìre àti àánú ni yóò máa tọ̀ mí lẹ́yìn ní ọjọ́ ayé è mi gbogbo, èmi yóò sì máa gbé inú ilé Olúwa títí láéláé.