< Ndari 33 >
1 Maya nĩmo matĩĩna ma rũgendo rwa andũ a Isiraeli rĩrĩa moimire bũrũri wa Misiri marĩ ikundi matongoretio nĩ Musa na Harũni.
Wọ̀nyí ni ìrìnàjò àwọn ọmọ Israẹli ní ẹsẹẹsẹ, nígbà tí wọ́n tí ilẹ̀ Ejibiti jáde wá pẹ̀lú àwọn ogun wọn, nípa ọwọ́ Mose àti Aaroni.
2 Musa nĩandĩkire matĩĩna ma rũgendo rwao o ta ũrĩa aathĩtwo nĩ Jehova. Maya nĩmo matĩĩna ma rũgendo rwao.
Mose sì kọ̀wé ìjáde lọ wọn ní ẹsẹẹsẹ gẹ́gẹ́ bí ìrìnàjò wọn, nípa àṣẹ Olúwa, wọ̀nyí sì ni ìrìnàjò wọn gẹ́gẹ́ bí ìjáde lọ wọn.
3 Andũ a Isiraeli moimagarire kuuma Ramesese mũthenya wa ikũmi na ĩtano mweri wa mbere, mũthenya ũrĩa warũmĩrĩire Bathaka. Makiumagara momĩrĩirie, makĩonagwo nĩ andũ othe a Misiri,
Àwọn ọmọ Israẹli jáde kúrò láti Ramesesi ní ọjọ́ kẹ́ẹ̀dógún oṣù kìn-ín-ní, ọjọ́ kan lẹ́yìn àjọ ìrékọjá. Wọ́n yan jáde pẹ̀lú ìgboyà níwájú gbogbo àwọn ará Ejibiti.
4 arĩa maathikaga marigithathi mao mothe, marĩa Jehova ooragĩte gatagatĩ kao; nĩgũkorwo Jehova nĩatuĩrĩire ngai ciao ciira.
Tí wọ́n sì ń sin gbogbo àkọ́bí wọn, ẹni tí Olúwa ti gbé lulẹ̀ láàrín wọn; nítorí tí Olúwa ti mú ẹ̀san wá sórí àwọn òrìṣà wọn.
5 Andũ a Isiraeli moima Ramesese, maambire hema Sukothu.
Àwọn ọmọ Israẹli kúrò ní Ramesesi wọ́n sì pàgọ́ sí Sukkoti.
6 Moima Sukothu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Ethamu, ndeere-inĩ cia werũ.
Wọ́n kúrò ní Sukkoti, wọ́n sì pàgọ́ sí Etamu, ní ẹ̀bá aginjù.
7 Moima Ethamu, maacookire na thuutha magĩthiĩ Pi-Hahirothu, mwena wa irathĩro wa Baali-Zefoni, makĩamba hema ciao hakuhĩ na Migidoli.
Wọ́n kúrò ní Etamu, wọ́n padà sí Pi-Hahirotu sí ìlà-oòrùn Baali-Ṣefoni, wọ́n sì pàgọ́ sí ẹ̀bá Migdoli.
8 Moima Pi-Hahirothu, magĩtuĩkanĩria iria-inĩ gatagatĩ, magĩkinya werũ-inĩ, na maarĩkia gũthiĩ rũgendo rwa mĩthenya ĩtatũ werũ-inĩ ũcio wa Ethamu, makĩamba hema ciao Mara.
Wọ́n sì dìde láti lọ kúrò ní iwájú Pi-Hahirotu, wọ́n sì la àárín òkun kọjá lọ sí aginjù. Wọ́n sì rin ìrìn ọjọ́ mẹ́ta ní aginjù Etamu, wọ́n sì pàgọ́ sí Mara.
9 Moima Mara maathiire Elimu, kũrĩa kwarĩ na ithima ikũmi na igĩrĩ, na mĩtende mĩrongo mũgwanja, na makĩamba hema kuo.
Wọ́n kúrò ní Mara wọ́n sì lọ sí Elimu, níbi tí orísun omi méjìlá àti igi ọ̀pẹ àádọ́rin gbé wà, wọ́n sì pàgọ́ níbẹ̀.
10 Moima Elimu magĩthiĩ makĩamba hema ciao hakuhĩ na Iria Itune.
Wọ́n kúrò ní Elimu wọ́n sì pàgọ́ sí ẹ̀bá Òkun Pupa.
11 Moima Iria Itune, magĩthiĩ makĩamba hema ciao werũ-inĩ wa Sini.
Wọ́n kúrò ní ẹ̀bá Òkun Pupa wọ́n sì pàgọ́ sínú aginjù Sini.
12 Moima werũ ũcio wa Sini, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Dofika.
Wọ́n kúrò nínú aginjù Sini wọ́n sì pàgọ́ sí aginjù Dofka.
13 Moima Dofika, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Alushu.
Wọ́n kúrò ní Dofka wọ́n sì pàgọ́ ní Aluṣi.
14 Moima Alushu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Refidimu, handũ hataarĩ na maaĩ ma kũnyuuo nĩ andũ.
Wọ́n kúrò ní Aluṣi wọ́n sì pàgọ́ ní Refidimu níbi tí kò sí omi fún àwọn ènìyàn náà láti mu.
15 Moima Refidimu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Werũ-inĩ wa Sinai.
Wọ́n kúrò ní Refidimu wọ́n sì pàgọ́ ní aginjù Sinai.
16 Moima kũu Werũ-inĩ wa Sinai, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Kibirothu-Hataava.
Wọ́n kúrò ní aginjù Sinai wọ́n sì pàgọ́ ní Kibirotu-Hattaafa.
17 Moima Kibirothu-Hataava magĩthiĩ makĩamba hema ciao Hazerothu.
Wọ́n kúrò ní Kibirotu-Hattaafa wọ́n sì pàgọ́ ní Haserotu.
18 Moima Hazerothu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Rithima.
Wọ́n kúrò ní Haserotu wọ́n sì pàgọ́ ní Ritma.
19 Moima Rithima, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Rimoni-Perezu.
Wọ́n kúrò ní Ritma wọ́n sì pàgọ́ ní Rimoni-Peresi.
20 Moima Rimoni-Perezu magĩthiĩ makĩamba hema ciao Libina.
Wọ́n kúrò ní Rimoni-Peresi wọ́n sì pàgọ́ ní Libina.
21 Moima Libina, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Risa.
Wọ́n kúrò ní Libina wọ́n sì pàgọ́ ní Rissa.
22 Moima Risa, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Kahelatha.
Wọ́n kúrò ní Rissa wọ́n sì pàgọ́ ní Kehelata.
23 Moima Kahelatha, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Kĩrĩma-inĩ gĩa Sheferu.
Wọ́n kúrò ní Kehelata wọ́n sì pàgọ́ ní orí òkè Ṣeferi.
24 Moima Kĩrĩma-inĩ gĩa Sheferu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Harada.
Wọ́n kúrò lórí òkè Ṣeferi wọ́n sì pàgọ́ ní Harada.
25 Moima Harada, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Makelothu.
Wọ́n kúrò ní Harada wọ́n sì pàgọ́ ní Makhelotu.
26 Moima Makelothu magĩthiĩ makĩamba hema ciao Tahathu.
Wọ́n kúrò ní Makhelotu wọ́n sì pàgọ́ ní Tahati.
27 Moima Tahathu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Tera.
Wọ́n kúrò ní Tahati wọ́n sì pàgọ́ ní Tẹra.
28 Moima Tera, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Mithika.
Wọ́n kúrò ní Tẹra wọ́n sì pàgọ́ ní Mitka.
29 Moima Mithika, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Hashimona.
Wọ́n kúrò ní Mitka wọ́n pàgọ́ ní Haṣmona.
30 Moima Hashimona, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Moserothu.
Wọ́n kúrò ní Haṣmona wọ́n sì pàgọ́ ní Moserotu.
31 Moima Moserothu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Bene-Jaakani.
Wọ́n kúrò ní Moserotu wọ́n sì pàgọ́ ní Bene-Jaakani.
32 Moima Bene-Jaakani, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Horu-Hagidigadi.
Wọ́n kúrò ní Bene-Jaakani wọ́n sì pàgọ́ ní Hori-Haggidgadi.
33 Moima Horu-Hagidigadi, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Jotibatha.
Wọ́n kúrò ní Hori-Haggidgadi wọ́n sí pàgọ́ ní Jotbata.
34 Moima Jotibatha, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Abirona.
Wọ́n kúrò ní Jotbata wọ́n sì pàgọ́ ní Abrona.
35 Moima Abirona, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Ezioni-Geberi.
Wọ́n kúrò ní Abrona wọ́n sì pàgọ́ ní Esioni-Geberi.
36 Moima Ezioni-Geberi, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Kadeshi, Werũ-inĩ wa Zini.
Wọ́n kúrò ní Esioni-Geberi wọ́n sì pàgọ́ ní Kadeṣi nínú aginjù Sini.
37 Moima Kadeshi, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Kĩrĩma-inĩ kĩa Horu, mũhaka-inĩ wa Edomu.
Wọ́n kúrò ní Kadeṣi wọ́n sì pàgọ́ ní orí òkè Hori, lẹ́bàá Edomu.
38 O ta ũrĩa aathĩtwo nĩ Jehova-rĩ, Harũni ũrĩa mũthĩnjĩri-Ngai akĩambata Kĩrĩma kĩa Horu, harĩa aakuĩrĩire mũthenya wa mbere wa mweri wa gatano, mwaka-inĩ wa mĩrongo ĩna kuuma andũ a Isiraeli moima bũrũri wa Misiri.
Nípa àṣẹ Olúwa, Aaroni àlùfáà gùn orí òkè Hori, níbẹ̀ ni ó kú. Ní ọjọ́ kìn-ín-ní oṣù karùn-ún, ọdún ogójì, lẹ́yìn tí àwọn ọmọ Israẹli ti ilẹ̀ Ejibiti jáde wá.
39 Harũni aarĩ na ũkũrũ wa mĩaka igana rĩa mĩrongo ĩĩrĩ na ĩtatũ rĩrĩa aakuĩrĩire kũu Kĩrĩma kĩa Horu.
Aaroni jẹ́ ẹni ọgọ́fà ọdún ó lé mẹ́ta ní ìgbà tí ó kú sí orí òkè Hori.
40 Nake Aradi mũthamaki wa Kaanani ũrĩa watũũraga Negevu ya Kaanani, akĩigua atĩ andũ a Isiraeli maarĩ njĩra magĩthiĩ kuo.
Àwọn ará Kenaani, ọba Aradi, tí ń gbé ìhà gúúsù ní ilẹ̀ Kenaani gbọ́ pé àwọn ọmọ Israẹli ń bọ̀.
41 Moima Kĩrĩma kĩa Horu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Zalimona.
Wọ́n kúrò ní orí òkè Hori, wọ́n sì pàgọ́ ní Salmona.
42 Moima Zalimona, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Punoni.
Wọ́n kúrò ní Salmona wọ́n sì pàgọ́ ní Punoni.
43 Moima Punoni, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Obothu.
Wọ́n kúrò ní Punoni wọ́n sì pàgọ́ ní Obotu.
44 Moima Obothu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Iye-Abarimu, mũhaka-inĩ wa Moabi.
Wọ́n kúrò ní Obotu wọ́n sì pàgọ́ ní Iye-Abarimu, ní agbègbè Moabu.
45 Moima Iyimu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Diboni-Gadi.
Wọ́n kúrò ní Iyimu, wọ́n sì pàgọ́ ní Diboni-Gadi.
46 Moima Diboni-Gadi, magĩthiĩ makĩamba hema ciao Alimoni-Dibilathaimu.
Wọ́n kúrò ní Diboni-Gadi wọ́n sì pàgọ́ ní Alimon-Diblataimu.
47 Moima Alimoni-Dibilathaimu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao irĩma-inĩ cia Abarimu hakuhĩ na Nebo.
Wọ́n kúrò ní Alimon-Diblataimu wọ́n sì pàgọ́ sí orí òkè Abarimu lẹ́bàá Nebo.
48 Moima irĩma-inĩ cia Abarimu, magĩthiĩ makĩamba hema ciao werũ-inĩ wa Moabi hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Jorodani mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa Jeriko.
Wọ́n kúrò ní orí òkè Abarimu wọ́n sì pàgọ́ ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu lẹ́bàá Jordani ní ìkọjá Jeriko.
49 Maambire hema hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Jorodani kuuma Bethi-Jeshimothu nginya Abeli-Shitimu, kũu werũ-inĩ wa Moabi.
Níbí ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu wọ́n pàgọ́ lẹ́gbẹ́ Jordani láti Beti-Jeṣimoti títí dé Abeli-Ṣittimu.
50 Kũu werũ-inĩ wa Moabi hũgũrũrũ-inĩ cia Rũũĩ rwa Jorodani mũrĩmo ũrĩa ũngĩ wa Jeriko, nĩkuo Jehova erĩire Musa atĩrĩ,
Ní pẹ̀tẹ́lẹ̀ Moabu, lẹ́bàá Jordani, létí Jeriko, Olúwa sọ fún Mose pé,
51 “Arĩria andũ a Isiraeli, na ũmeere atĩrĩ: ‘Rĩrĩa mũkaaringa Rũũĩ rwa Jorodani mũtoonye Kaanani-rĩ,
“Sọ fún àwọn ọmọ Israẹli kí o sì wí fún wọn pé, ‘Ní ìgbà tí ẹ̀yin bá ń rékọjá odò Jordani lọ sí Kenaani,
52 mũkaaingata andũ arĩa othe matũũraga bũrũri ũcio, mehere mbere yanyu. Mũkaananga mĩhianano yao yothe ĩrĩa mĩicũhie, na mĩhianano yao ĩrĩa ya gũtwekio, o na mũmomore mahooero mao mothe ma kũndũ kũrĩa gũtũũgĩru.
lé gbogbo àwọn ará ilẹ̀ náà kúrò níwájú yín. Run gbogbo àwòrán ère wọn àti gbogbo ère dídá wọn, kí ẹ sì wó gbogbo ibi gíga wọn palẹ̀.
53 Mwĩnyiitĩrei bũrũri ũcio ũtuĩke wanyu na mũtũũre kuo, nĩgũkorwo nĩ ndĩmũheete bũrũri ũcio ũtuĩke wanyu.
Ẹ gba ilẹ̀ náà, kí ẹ̀yin sì máa gbé inú rẹ̀, nítorí èmi ti fi ilẹ̀ náà fún yín gẹ́gẹ́ bí ìní yín.
54 Mũkaagayania bũrũri ũcio na ũndũ wa kũũcukĩra mĩtĩ, kũringana na mĩhĩrĩga yanyu. Kũrĩ gĩkundi kĩnene mũheane igai inene, na gĩkundi kĩnini mũkĩhe igai inini. Kĩrĩa gĩkaamagũĩra na ũndũ wa gũcuuka mĩtĩ nĩkĩo gĩgaatuĩka kĩao. Nĩmũgakũgayania kũringana na mĩhĩrĩga ya maithe manyu ma tene.
Ẹ̀yin pín ilẹ̀ náà pẹ̀lú kèké, gẹ́gẹ́ bí ìdílé yín. Fún ọ̀pọ̀ ni kí ẹ̀yin ó fi ilẹ̀ ìní púpọ̀ fún, àti fún díẹ̀, ni kí ẹ̀yin kí ó fi ilẹ̀ ìní díẹ̀ fún. Ohunkóhun tí ó bá bọ́ sí ọ̀dọ̀ wọn nípa kèké yóò jẹ́ tiwọn. Pín wọn gẹ́gẹ́ bí ẹ̀yà ìran wọn.
55 “‘No mũngĩkaaga kũingata atũũri a bũrũri ũcio-rĩ, arĩa mũgeetĩkĩria matigwo magaatuĩka ngaracũ cia kũmũtũraga maitho, o na matuĩke mĩigua ya kũmũtheecaga mbaru. Nao nĩmakamũthĩĩnagia kũu bũrũri ũcio mũgaatũũra.
“‘Ṣùgbọ́n bí ẹ kò bá lé àwọn ará ilẹ̀ náà kúrò níwájú yín, àwọn tí ẹ bá jẹ́ kí ó kù yóò di ọfà nínú ojú yín, àti ẹ̀gún ní ìhà yín. Wọn yóò fún yín ní wàhálà ní ilẹ̀ náà tí ẹ̀yin yóò gbé.
56 Na rĩrĩ, ũndũ ũrĩa ndaciirĩire kũmeka-rĩ, ũtuĩke nĩguo ngaamwĩka inyuĩ.’”
Nígbà náà, èmi yóò ṣe sí yín, ohun tí mo ti rò láti ṣe sí wọn.’”